Lọ́nà
àti wojutu soro àwọn ọmọ ilẹ̀ Nàìjíríà tó ń gbé làwọn ilẹ̀ ókéré àti láti dènà
àwọn èèyàn kúrò lọ́wọ́ bí wọ́n ṣe ń fi wọ́n sowo lairo tì, àwọn ilé isẹ
igbohunsafefe gbọ́dọ̀ gunle gbígbé àwọn ìròyìn tó yẹ jáde lọ́nà àti lè jẹ́
káwọn èèyàn mọ àwọn nǹkan tó tọ́ fún wọn láti ṣe.
Èyí
lafenuko àwọn tọrọ kan níbi ètò kan tonise pẹ̀lú ìròyìn latenubode, lo wáyé
nilu Èkó.
Àgbà
oje oniroyin kan, ọmọwe Theophilus Abbah woye pé, ojúṣe àwọn ilé – isẹ
igbohunsafefe ní, láti pe àkíyèsí àgbáyé lọkan o jokan ìṣòro àtàwọn ìṣẹ̀lẹ̀
meriri tó ń ṣẹlẹ̀ sáwọn arìnrìn-àjò nílè Libya.
Fasasi/Ogunkola.
pub-5160901092443552