Home Posts tagged Bùkátà
Yoruba

Àjọ NACA, Sètò Ikòwójọ Láti Gbọ́ Bùkátà Aàrùn Aids Lai Wojú Onígbọ̀wọ́

Àjọ tó n se kòkárí ọ̀rọ̀ nípa kòkòrò àjàkálẹ̀ àrùn AIDs nílẹ̀ yí NACA, ti se ìfilọ́lẹ̀ ètò ìkówójọ lábẹ́lé fún ìdúrósinsin àjọ náà, láti ọdún 2021 sí ọdún 2025, lọ́nà ti orílẹ̀dè yi yóò fi bọ́ lọ́wọ́ gbígbé ara lé àrùn onígbọ̀wọ́ ilẹ̀ òkèèrè fún ètò ìsúná àjọ náà pẹ̀lú àfojúsùn wọn ọdún 2030. Continue Reading