Ìgbìmọ̀ alásẹ ìjọba àpapọ̀ ti buwọ́lu owó tó lé ní áàdọ́jọ billiọnu naira fún síse àwọn òpópónà méje káàkiri ilẹ̀ yí. Alákoso fọ́rọ̀ isẹ́ òde àti ilégbe, ọ̀gbẹ́ni Babatunde Fashọla ló sọ̀rọ̀ lórí àbájáde ìpàdé wọn nílu Abuja. Alákoso ní àwọn ọ̀nà náà yíò pèsè isẹ́ fún àwọn ẹgbẹ̀rún mẹ́ta Continue Reading
Yoruba News
Weekend Treat
Trending Now
Recent Posts
Categories
Archives
iframe: google.com, pub-5160901092443552, DIRECT, f08c47fec0942fa0
This is the head of your page
This is the body of your page.