Home Posts tagged Orílẹ̀ Ede Benin
Yoruba

Ilé Ejọ́ Orílẹ̀ Ede Benin bẹ̀rẹ̀ ìgbẹ́jọ́ lórí ọrọ Sunday Igboho

Ilé ẹjọ́ tó fi ilẹ̀ olóminira Benin sebujoko yio gbọ ẹjọ́ lóni bóyá kí wọ́n fi ajìjàgbara fún ìdásílẹ̀ orílẹ̀ èdè Oodua nì Olóyè Sunday Adeyẹmọ tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Sunday Igboho sọwá síll yí. Agbẹnusọ fún Olóyè Sunday Igboho, Ọlayọmi Koiki ẹnití ó sọ̀rọ̀ yí di mímọ̀ fáwọn oníròyìn sọ wípé Continue Reading