Oludari ajo abo ara eni laabo ile, Nigeria Security and Civil Defence Corps, NSCDC, eka tipinle Oyo, Ogbeni Michael Adaralewa ti sefi lole iko kan ti yoo maa gbogun ti awon ayederu eso alaabo.

Iko amuseya naa, niwon mu won lati eka aladani tiwon je akosemose osise, alaabo nile yi, eka tipinle Oyo.

Nibi ifilole Iko amuseya naa, Ogbeni Adaralewa fimo awon omo egbe ohun lati karamasiki mo ise tiwon gbele won lowo, nibanu pelu ohun tiwon to e gbewon kale, lati forwo kilanko awon ayederu eso alaabo kuro ninu awon ewo alaabo tiwon je ojulowo nipinle Oyo.

O wa sekilo fawon eeyan awujo, lati ye maa lo soro awon eso alaabo ti ko ni iwe ase isise tabi ni akosile kenikeni lodo awon ajo torokan, lti dena isele ijinigbe, ifipa balopo to fimawon alonilowogba.

Folakemi Wojuade

pub-5160901092443552

Related Posts

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *