Àjọ ton mojuto idagbasoke eto ìlera alabode nipinle Ogun pẹ̀lú ifowosowopo ìgbìmò tó ń risi ọrọ ìlera ojú nipinle náà tí sàgbékalè ètò ayẹwo ojú lofe fáwọn onimoto, ero àtàwọn aladani láwọn ibùdóko jákèjádò ìpínlè náà gẹ́gẹ́bí ara eto ton sàmìń ayajo ọjọ́ iriran tóko lọ́dún yi. Nígbà tó ń Continue Reading
Yoruba
Ègbé olùkọ́ láwọn ilé ẹ̀kọ́ Fáṣítì nileyi, ASUU tí sewele iyanselòdi olosu mejo rẹ pẹ̀lú àwọn afẹnukò ìlànà kan. Alága ẹgbẹ́ náà fún olú ìlú wa Abuja, Ojogbon Kasimio Umar ló fìdí ọ̀rọ̀ náà múlè fáwọn akoroyin nilu Abuja. Ègbé náà pinnu láti fòpin sí iyanselòdi ohun lásìkò ìpàdé àwọn adarí tó bẹ̀rẹ̀ lalẹ àná […]Continue Reading
Ijoba Ipinle Ogun ti fi ipinnu re han lati mu atunto to wuyi de ba eka irin ajo afe atawon gbongan asa ibile pelu eron gba lati je kowo to nwole si akoto oba nipinle ohun ko tubo rugoogo sii. Alamojuto foro asa ati irin ajo afe nipinle Ogun Arabinrin Motunrayo Adeleke Oladapo lo siso […]Continue Reading
Ní itesiwaju ètò ìwóde tégbé òsìsé NLC gùnlé yíka orilede Nigeria, èyí tó ti wo ojó kejì bayii, Egbé náà atawon akegbé rè ti wode yíká ìlú Abuja loni. Ìròyìn sopé, lati nnkan bi ago méje òwúrò Òní lawon òsìsé ti peju- pese si unity Fountain feto ìwóde náà. Níbáyìnáá, ètò àbò ti gbóná girigiri, […]Continue Reading
Ètò ìwóde Egbé àwon òsìsé NLC ti wáyé yíká àwon ìpínlè lorilede yí. Ètò ìwóde náà tegbe àwon òsìsé gùnlé lo wáyé láti fi sàtìleyìn fun ìyansélódì Egbé ASUU to nlo lówó, tíwón si tún fi n sàfihàn àìdùnú lori owó tíjoba àpapò mórò ìyansélódì olósè méjìlá Egbé ASUU náà. Àbò ìròyìn láti àwon ìpínlè […]Continue Reading
Baamòfin fun agbègbè Òkè- Ògùn, títún se, Agbejórò Àgbà nílè yí, Olóyè Jelili Owonikoko, ti sàpéjúwe Aséyìn tìlú ìséyìn to wàjà, Oba Abdulganiyu Adekunle, gégé bí olórí tí gbogbo àwon èèyàn bòwò fun , tíwón si tún fenípò pelu, fún gbogbo àkókò to Lori àpèrè àwon baba ñla rè. Nínú ìwé ìbánikédùn tó ko , […]Continue Reading
Bí igba ọdún dìẹ làwọn akẹ́kọ́ọ̀ ilé-ìwé alákọbẹ̀rẹ̀ tó jóko sèdáwò àyẹ̀wò bákẹ̀kọ́ kan se gbéwọ̀n sí láti wọ ile ẹ̀kọ́ girama nípinlẹ̀ ọ̀yọ́. Alákoso fétò ẹ̀kọ́ ìmọ̀ sáyẹ̀nsì àti tìmọ̀ ẹ̀rọ nípinlẹ̀ ọ̀yọ́, ọ̀gbẹ́ni Rahman Abdul-Raheem ló kéde bẹ́ẹ̀ nílu Ìbàdàn, bẹ́ẹ̀ lósì fi ìdùnú rẹ̀ hàn lórí, bẹ́tò ìdánwò náà fún tọdún 2022 […]Continue Reading
Wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ sí níì gbé àwọn aláàjì láti orílẹ̀ èdè Saudi Arabia padà wa sílẹ̀. Báàlù pẹ̀lú nọ́mbà ìmínimọ̀ xy7002 tó gbé àwọn aláàjì tó lé ní irinwó láti olú ìlú ilẹ̀ yí lọ gbéra kúrò ní pápá òfurufú ọba Abdulazeez tó wà ní Jeddah wá sí pápákọ̀ Nnamdi Azikwe nílẹ̀ yí. Alága àjọ […]Continue Reading
Àjọ elétò ìdìbò ilẹ̀ yí, INEC, ti pín àwọn ohun èèlò ìdìbò sáwọn ìjọba ìbílẹ̀ ọgbọ̀n ní ìpalẹ̀mọ́ fún ètò ìdìbò sípò Gómìnà tí yio wáyé nípinlẹ̀ Ọsun lọ́la. Pínpín àwọn ohun èèlò ìdìbò ọ̀hún ló wáyé ní ọ́fìsì INEC, tó wà l’ósogbo níbití àwọn asájú ẹgbẹ́ òsèlú, àwọn oníròyìn àti ònwòye ètò ìdìbò péjú […]Continue Reading
Àarẹ ilẹ̀ America, Joe Biden ni yio se pàdépọ̀ pẹ̀lú àwọn adarí ilẹ̀ Palestine tí wọ́n wà lágbègbè West Bank lóni sáàjú kó tó lọ síbi ìpàdé àpérò ni Saudi Arabia. Gẹ́gẹ́bí ohuntí àwọn ònwòye sọ, ó seese kí ǹkan lọ́ jái níbi ìpàdé náà pẹ̀lú Mahmoud Abbas nítorí gbúngbùngbún tó wà láàrin wọn pẹ̀lú […]Continue Reading
Àarẹ Muhammadu Buhari ti kí ikọ̀ agbágbbọ̀ọ̀lù Super Falcons kú oríìre àseyọrí wọn nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ wọn pẹ̀lú ikọ̀ Indomitable Lioness ti Cameroon pẹ̀lú àmì ayò kan sí òdo nínú ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ ìpele kejì tó kángun sí àsekágbá níbi ìdíje ife ẹ̀yẹ ilẹ̀ adúláwọ̀ tàwọn Obìnrin tọdún 2022 tó ńlọ ní Morocco. Àtẹ̀jáde látọ̀dọ̀ amúgbálẹ́gbẹ àarẹ lórí […]Continue Reading
Ijoba Ipinle Eko nipase ajo to n mojuto imototo ayika, LASEPA, ti ro awon eni orokan leka ipese nkan lori amojuto awon kemika to lewu. Oga agba ajo LASEPA, Omowe Dolapo Fasawe, to soro naa lasiko eto idanileko awon eni-orokan nilu Eko, wa pe awon olupese nkan nija lati je akosemose lori ise ti won […]Continue Reading
Ile ise ijoba apapo to n ri soro igbokegbodo oko ti gunle eto didekun awon ibudo ti o bofin mu, ohun fifopin si iwa ajebanu lawon oju ona to lo sibudoko oju omi nilu Eko. Akowe agba nile ise ohun, Arabinrin Magdalene Ajani to salaye pe ko din ni ibudo ayewo merindinlogbon ni ko ba […]Continue Reading
Aare ile Igbimo Asofin agba ile yi, Omowe Ahmad Lawan ti sefilole igbimo eleni metala tah tana wadi bi won se nji eroja epo robi ati ipa re lori ipese epo ohun owo to n wole lori re. O kede odo yi nibi ijoko ile. Omowe Lawan wa kede Senator Bassey Alber-Akpan gegebi alaga igbimo […]Continue Reading
Bi awon omoleyin Kristi ile yi ti se darapomo awon akegbe won kaakiri agbaye lati sami iku Jesu Oluwa, ojise Olorun kan, Apostle Peter Akanji tipe fun emi ifaraeniji ati ife tawon adari. Nigbati o nsoro lori Pataki ojo eti rere, Oludari ijo World Ourtreach Revival Center, WOREC nilu Ibadan ni ojo oni safihan ife […]Continue Reading
Gómìnà ìpínlẹ̀ ọ̀sun, ọ̀gbẹ́ni Adegboyega Oyetọla, ti síjú áànu wo àwọn ẹlẹ́wọ̀n mọ́kànlá tó wá láwọn ibùdó àtúnse ìlú Ilésà àti Ilé-Ifẹ, tó sì dáwọn sílẹ̀. Gómìnà Oyetọla tó sanwó ìtanràn àwọn ẹlẹ́wọ̀n mọ́kànla náà lákokò àyẹ̀wò tó gbópọn lórí ẹ̀sùn wọn, sọ pé, ìgbésẹ̀ náà wáyé láti mú àdínkù bá báwọn ibùdó àtúnse náà […]Continue Reading
Ijọba àpapọ̀ ti sàwárí òsìsẹ́ tó lé ní ẹgbẹ̀rún kan àtàbọ́, tójẹ́ pé ìwé ìgbanisísẹ́ ayédèrú ni wọ́n lò láti darapọ̀ mọ́ isẹ́ ìjọba. Olórí òsìsẹ́ nílẹ̀ yí, ọ̀mọ̀wé Fọlasade Yẹmi-Ẹsan ló sọ̀rọ̀ yí di mímọ̀ nílu Abuja. Ọmọwe Yẹmi-Ẹsan sọpé ó lé ní ẹgbẹ̀rún kan àwọn èyàn tí wọ́n sàwárí ní ẹ̀ka ilésẹ́ kan, […]Continue Reading
Ìjọba àpapọ̀ ti pè fún àmójútó tó péye láàrin àwọn tọ́rọ̀ kàn nídi àti fòpin sí lílo ọmọdé nílòkulò nílẹ̀ Nàijírìa. Akọ̀wé àgbà iléesẹ́ ìjọba àpapọ̀ tó wà fún ọ̀rọ̀ òsìsẹ́ àti ìgbanisísẹ́, Dókítà Yerima Peter-Tarfa ló pèpè yí nílu Abuja lásìkò ètò ìdánilẹ́kọ tó wáyé fáwọn olùdarí ẹkùn àti alámojútó láwọn ìpínlẹ̀ nípa ètò […]Continue Reading
Olúbàdàn tilẹ̀ ìbàdàn ọba Lekan Balogun ti sìkìlọ̀ fáwọn atọ́kùn ègùngùn, àtàwọn tó fẹ́ báwọn kọwọ ọdún pé kí wọ́n yàgò fún jàgídíjàgan lásìkò ayẹyẹ ọdún ilẹ̀ ìbàdàn tí yóò bẹ̀rẹ̀ lósù tó n bọ̀. Ọba Balogun sàlàyé ọ̀rọ̀ yí lásìkò àbẹ̀wò alágbáà tíì se olórí àwọn egùngùn nílé olúbàdàn tó wà ní alárere. Ọba […]Continue Reading
Òjò alágbára tó rọ̀ nílu’bàdàn lána òde yi ti ba àwọn ilégbe iléwe tófimọ́ òpó iná jẹ́. Akọ̀ròyìn ilésẹ́ Radio Nigeria tó tọpinpin ìsẹ̀lẹ̀ náà, jábọ̀ pé òrùlé àwọn ilégbe kan lágbugbò Agbowó àti orogún ni ìjì ọ̀hún gbé lọ. Yàtọ̀ fún àwọn ìgì tó wọ́lu ojú òpópónà, àwọn irinsẹ́ tón mú iná wọlé ilésẹ́ […]Continue Reading
Àwọn ẹlẹ́ri Jèhófà nílẹ̀ yí àti káàkiri àgbáyé ni wọn yio si gbọ̀gàn ìpàdé wọn padà lọ́jọ́ ẹtì ọ̀sẹ̀ yí lẹ́yìn tí wọ́n ti gbéè tì padà fún bíì ọdún méjì níbamu pẹ̀lú ìlànà áàbò àti dènà ìtànkálẹ̀ àrùn covid 19. Àtẹ̀jáde látọ̀dọ̀ olú ile isẹ́ àwọn ẹlẹ́ri Jèhóvàh sọ wípé àkànseàsọyé ọlọ́gbọ̀n ìsẹ́jú tí […]Continue Reading
Ilésẹ́ tón rísí ìrìnà ojú irin ti fòfinde ìrìnà láti Abuja lọ sí Kaduna, tí kò sì ní gbèdéke. Ilésẹ́ náà ló jẹ́ kọ́rọ̀ yí di mímọ̀ nínú ọ̀rọ̀ tó fi síta lójú òpó abẹ́yẹ fò twitter rẹ̀ lóòrọ yi. Ó sọ pé ìfòfindè náà ló wáyé fún àwọn ìdí tí wọ́n kò lérò, tó […]Continue Reading
Igbákejì Àrẹ, Yẹmi Ọsinbajo ti kéde ìdásílẹ̀ ètò ìdàgbàsókè mẹ́fà èyí tí ìjọba àpapọ̀ fẹ́ gùnlé láwọn lẹkun kọ̀kan nílẹ̀ yí, láti lè mú kí àgbéga débá ọrọ̀ ajé láwọn ìpínlẹ̀. Igbákejì Àrẹ kédeyi lásìkò àpérò ilẹ̀ adúláwọ̀ níbi tí àtúntò fọ́dún 2022 yo ti wáyé nílu Abuja. Ọjọgbọn Ọsinbajo sọ fún àwọn akópa pé […]Continue Reading
O se Pataki ki ajosepo was laarin ijoba ni gbogbo eka ati ileese aladani lati mu ki amugbooro de ba nini anfani si eto ilera to koju owo. Igbakeji Aare, Ojogbon Yemi Osinbajo lo soro yi lasiko to n siso loju ipade apero eto ilera alabode kan nilu Abuja. Ojogbon Osinbajo tenumo pe ibasepo laarin […]Continue Reading
Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó ti pàrọwà fáwọn onímọ̀tó láti ní ẹ̀mí ìgbọ́raẹniyé lórí bí wọ́n tise ńgberò àti bẹ́ẹ̀rẹ̀ síì gbowó padà lẹ́nu ìloro Lẹ́kkí. Alákoso fọ́rọ̀ ìròyìn nípinlẹ̀ Èkó ọ̀gbẹ́ni Gbenga Ọmọtọsọ ló pàrọwà yí nílu Èkó. Ọgbẹni Ọmọtọsọ tẹnumọ́ ìdí tí àwọn olùgbé ìpínlẹ̀ Èkó fi gbọdọ̀ máà fojú áànu wo àwọn òsìsẹ́ ẹnu […]Continue Reading