Ilé ìgbìmò asòfin Àgbà ti kò jálè láti fowósí ìyànsípò Lauretta Onochie gégé bí Alákoso fájo elétò ìdìbò ilè yìí, Inec.

Alága ìgbìmò náà, Kabiru Gaya so nínú àbò rè pé, Onochie ni kò kún ojú òsúnwòn tíjoba àpapo làkalè.

Tílé Asòfin àgbà òhún sì dìbò tako ìyànsípò rè.

Wojuade

pub-5160901092443552

Related Posts

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *