Yoruba

Bí Igba Làwọn Akẹ́kọ́ọ̀ tó Jóko Sèdánwò Igbaniwọlé Sáwọn Iléwé Girama Nípinlẹ̀ Oyọ́

Bí igba ọdún dìẹ làwọn akẹ́kọ́ọ̀ ilé-ìwé alákọbẹ̀rẹ̀ tó jóko sèdáwò àyẹ̀wò bákẹ̀kọ́ kan se gbéwọ̀n sí láti wọ ile ẹ̀kọ́ girama nípinlẹ̀ ọ̀yọ́.

Alákoso fétò ẹ̀kọ́ ìmọ̀ sáyẹ̀nsì àti tìmọ̀ ẹ̀rọ nípinlẹ̀ ọ̀yọ́, ọ̀gbẹ́ni Rahman Abdul-Raheem ló kéde bẹ́ẹ̀ nílu Ìbàdàn, bẹ́ẹ̀ lósì fi ìdùnú rẹ̀ hàn lórí, bẹ́tò ìdánwò náà fún tọdún 2022 yíì se lọ yíká àwọn ìjọba ìbílẹ̀ tó ńbẹ nípinlẹ̀ ọ̀yọ́.

Nígbà tón sọ̀rọ̀ lórúkọ, alákoso náà, akọ̀wé àgbà fún ilé isẹ́ ètò ẹ̀kọ́ nípinlẹ̀ yíì, arábìnrin Christianah Abioye sàpèjúwe bí ìdánwò náà se lọ ní ìrọ́wọ́ rẹsẹ̀, tí kò sì sí ìwà màgògágó kankan nínú ètò ìdánwò àsewọlé ilé lkọ́ girama náà.

Ó wá mú dáwọn òbí àtàwọn èèyàn àwùjọ lójú pé, ìjọba tó wà lóde báyíì setán láti dágbogbo àwọn ọmọ tíkò simile we padpa sébẹ̀ lábẹ́ ìlànà ètò ẹ̀kọ́ ọ̀fẹ́ nípinlẹ̀ ọ̀yọ́

PR/Banjo/Wojuade

pub-5160901092443552

Related Posts

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *