Baamòfin fun agbègbè Òkè- Ògùn, títún se, Agbejórò Àgbà nílè yí, Olóyè Jelili Owonikoko, ti sàpéjúwe Aséyìn tìlú ìséyìn to wàjà, Oba Abdulganiyu Adekunle, gégé bí  olórí tí gbogbo àwon èèyàn bòwò fun , tíwón si tún fenípò pelu, fún gbogbo àkókò to Lori àpèrè àwon baba ñla rè.

Nínú ìwé ìbánikédùn tó ko , lolóyè Owonikoko ti fìdí rè múlè pe, Ìdàgbàsókè àti Ògo loba Adekunle mú wo ìlú ìséyìn, èyí tómú kiwon mòó jákè-jádò àgbáyé.

Ó tókasí pe, lákòkóò ìsàkóso oba alaye náà nílùú ìséyìn, ni won Yan Onidajo Olukayode Ariwoola gégé bí Adelé Adájó àgbà nílè Nigeria.

Olóyè Owonikoko kò sàì tún soódi mímò pé, ní pa tòrò àwùjo , ìgbà Aséyìn tìlú ìséyìn to wàjà náà, nílùú tùbà- tùse, tígbà sìro gbogbo àwon èèyàn agbègbè ìlú ìséyìn lórùn , nínú èyí ti , àyípadà rere ti débá àsà , ìse , àti ilosiwaju ìlú ìséyìn.

Owonikoko/Wojuade

pub-5160901092443552

Related Posts

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *