Home Posts tagged Ilé ìgbìmọ̀ asòfin
News Yoruba

Ilé ìgbìmọ̀ asòfin ńfẹ́kí àfikún débá owó fún ètò àbò nínú ìsúná

Ìgbìmọ̀ tón rírí isẹ́ ológun, nílé ìgbímọ̀ asòfin sọpé owónáà tójẹ́ billiọnu mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n naira tí wọ́n yà sọ́tọ̀ fún àwọn isẹ́ àkànse nílesẹ́ ológun nílẹ̀ Nàijírìa, nínú àbá ìsúná fún tọdún 2021, ni wọ́n sọpé kòtó rárá. Alága ìgbìmọ̀ náà, Sẹnatọ Alli Ndume Continue Reading
Yoruba

Ilé ìgbìmọ̀ asòfin jẹ́jẹ láti fọwọ́ òfin mú àwọn ilésẹ́ tokọ̀ láti sanwó tó yẹ sí koto jọba

Ilé ìgbìmọ̀ asòfin tiń ńdú koko pé, òn yo sàmúlò ọwọ́ òfin, fi de àwọn ilésẹ́ kan tí wọ́n kọ̀ láti san àwọn owó tó yẹ sí koto ìjọba àpapọ̀. Alága ìgbìmọ̀ ìsúná nílé asòfin James Faleke ló sọ̀rọ̀ yí lásìkò ìfọ̀rọ̀wérọ̀ pẹ̀lú àwọn ilésẹ́ ìjọba nílu Abuja. Ó tọ́kasi pé, àjọ tón mójútó ìpéye […]Continue Reading