
Ilésẹ́ tón rísí ìrìnà ojú irin ti fòfinde ìrìnà láti Abuja lọ sí Kaduna, tí kò sì ní gbèdéke. Ilésẹ́ náà ló jẹ́ kọ́rọ̀ yí di mímọ̀ nínú ọ̀rọ̀ tó fi síta lójú òpó abẹ́yẹ fò twitter rẹ̀ lóòrọ yi. Ó sọ pé ìfòfindè náà ló wáyé fún àwọn ìdí tí wọ́n kò lérò, tó […]Continue Reading