Home Posts tagged Mile 2
Yoruba

Ìjọba ìpínlẹ̀ èkó sèlérí pé isẹ́ àkànse kíkọ́ òpópónà apapa yo parí nínú ọdún yí

Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó ti sọpé gbogbo òpópónà àti afárá èyí tí wọ́n ńkọ́ lọ́wọ́ ládugbò Apapa ni yo jẹ píparí nínú osù kẹwa ọdún tawàyí. Gómìnà Babajide Sanwo-olu ló sọ̀rọ̀ ìdánilójú yi lásìkò tó se àbẹ̀wò láti mọ ibi tísẹ́ dé dúró lágbègbè náà, n’ípinlẹ̀ Èkó. Gómìnà Sanwo-olu, sọpé súnkẹrẹ Continue Reading