Home Posts tagged NLC.
Yoruba

Ẹgbẹ òsìsẹ́ àti ìjọba sún ìdúnadúrà lórí owó osù síwájú

Ìpàdé lórí ẹ̀kún owó osù oní ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgbọ̀n tí ẹgbẹ́ àwọn òsìsẹ́ àti ìjọba gùùnlé ni ó tún ti forí sọ́pọ́n nígbàtí wọ́n ò lee fẹnu kò síbi kan lẹ́yìn wákàtí mẹ́san tí wọ́n ti ńsèpàdé. Alákoso fọ́rọ̀ àwọn òsìsẹ́ àti ìgbanisísẹ́, Dókítà Chris Ngige nígbàtí ó n bá àwọn oníròyìn sọ̀rọ̀ nílu Abuja […]Continue Reading