Yoruba

Olùdarí àgbà ilésẹ́ Radio Nigeria ìbàdàn, tó fẹ́ fẹ̀yìntì, Àhájì Mohammed Bello, ńfẹ́ káwọn oníròyìn máà wádi ohun gbogbo kí wọ́n sì ridájú pé, ìròyìn tó fìdí múlẹ̀ nìkan ni wọn ńgbé síta fún ìsọ̀kan ilẹ̀ yíì.

Àlhájì Bello ẹnitó sọ̀rọ̀ yíì lásìkò tó ńkopa lórí ètò ilésẹ́ Premier F.M lédè gẹssi THE STAGE, sàlàyé pàtàkì bóse yẹ káwọn oníròyìn ma sisẹ́ wọn bí isẹ́ pẹ̀lú ìwà ọmọlúàbí kí wọ́n sì máà jábọ̀ isẹ́ ìríjú àwọn adarí fáwọn èeyàn àwùjọ.

Nígbà tó ńsèpèjúwe ilésẹ́ Radio Nigeria gẹ́gẹ́ bí ọ̀rẹ́ aráàlu, Àlhájì Bello sọ di mímọ̀ pé ilésẹ́ Radio Nigeria kòní káàrẹ láti máà fọnrere ìsọ̀kan ilẹ̀ yíì.

Àlhájì Bello ẹnitó kéde ìdásílẹ̀ ẹ̀ka ilésẹ́ Radio Nigeria titun méjì nípinlẹ̀ ọ̀yọ́, rọ àwọn agbègbè táwọn ilésẹ́ náà wáà, ní ìjọba ìbílẹ̀ Surulere àti Ògbómọ̀sọ́ láti sàmúlò àwọn ilésẹ́ náà bótiyẹ.

Aminat Jibikẹ/Idogbe Elizabeth

News

The Registrar, Chief Executive of Teachers Registration Council of Nigeria, Professor Josiah Ajiboye, has advocated for a higher standard living for teachers, to meet up with the international standards.

While featuring on The Stage, a personality interview programme on Premier FM 93.5, Ibadan, Professor Ajiboye said outside Nigeria, especially in countries like Finland and Germany, teachers are more highly paid than other professions as they are the best brains the country could boast of.

Professor Ajiboye noted that, if maximum attention was given to the needs of teachers, it would yield a positive impact on both the teachers and the students.

The Registrar Chief Executive of TRCN, however, said that only professional teachers should be strictly taken into the teaching sector for a better teaching standard.

Taiwo Akinola