Nigeria’s first female combat helicopter pilot, Tolulope Arotile, who died on July 14, will be buried next Thursday, July 23, the Nigerian Air Force said on Friday. The NAF said Arotile will be laid to rest with “full military honours at the National Military Cemetery in Abuja. A condolence Continue Reading
Ilésẹ́ ọmọ ológun òfurúfú sọpé àwọn ti pàdánù, obìrin àkọ́kọ́ tó ńwa ọkọ̀ báàlù ìjagun ọ̀gágun Tolulọpẹ Arotile, nínú ìjàmbá ọkọ̀ kan tówáyé nílu Kaduna. Ọga àgbà lẹ́ka ìròyìn nílesẹ́ ọ̀hún, ọ̀gágun Ibikunle Daramọla, kéede ìpapòdà ọ̀gágun Arotile nínú àtẹ̀jáde kan nílu Abuja. Ológbe ọ̀hún ló gba àgbéga lọ́dún tókọjá, látọwọ́ ọ̀gágun àgbà Saddique Abubakara […]Continue Reading