Ìjọba àpapọ̀ orílẹ̀èdè yíì ti rán ìgbìmọ̀ amúsẹ́yá lọ sípinlẹ̀ Kano, láti ló kápá àisàn pàjáwìrì kan tó bẹ́sílẹ̀ nípinlẹ̀ ọ̀hún.

Olùdarí àgbà pátápátá fún ibùdó tón rísí ìkápá àrùn lọ́lọ́kanòjọ̀kan nílẹ̀ yíì, NCDC, Dókítà Chikwe Ihekweazu ló sísọ lójú ọ̀rọ̀ yíì nílu Abuja lákokò ìpàdé alájùmọ̀se kan tígbìmọ̀ amúsẹ́yá tílesẹ́ àrẹ gbékalẹ̀ covid-19.

Ó sàlàyé pé, ìgbìmọ̀ amúsẹ́yá ọ̀hún yóò sàmójútó àwọn èèyàn bi ìgbà tó tilùgbàdì àisàn náà, pẹ̀lú àwọn èèyàn mẹ́rin tó ti tipasẹ́ rẹ̀ jáde láyé.

Dókítà Ihekweazu kò sài fikun pé, ilé-isẹ́ ètò ìlera ìpínlẹ̀ náà, sọ pé onírunru ẹ̀sùn làwọn tigbọ́ nípa àrùn náà, làwọn ìjọba ìbílẹ̀ bi mẹ́tàlá tón bẹ nípinlẹ̀ Kano, nínú èyí táisan iba, eebi kojú pọ́n àtàwọn èyí tíníse pẹ̀lú inu wa, gẹ́gẹ́bí àwọn àmì tíwọ́n ńrí.

Banjọ/Wojuade

pub-5160901092443552

Related Posts

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *