Yoruba

Gómìnà ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́ sètò gbà mábinú fẹ́bí àwọn tópadùn ẹ̀mí wọn nílu Ìsẹ́yìn

Gómìnà ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́, onímọ̀ ẹ̀rọ Seyi Makinde ti sèlérí milliọnu kọ̀kan naira fẹ́bí àwọn tó sọ ẹ̀mí won nù nípase aawọọ ìbọn yínyìn lárin àwọn òsìsẹ́ ẹ̀sọ́ asọ́bọdè àtàwọn onífàyàwọ́ to waye nílu Ìsẹ́yìn.

Ó sèlérí yíì lásìkò tó sàbẹ̀wò sáfin Asẹ́yìn ti Ìsẹ́yìn, ọba Abdulganiu Adekunle.

Gómìnà Makinde ẹnitó bẹnu àtẹ́lu ìsẹ̀lẹ̀ ọ̀hún ni ìjọba ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́ yóò gbé ìgbésẹ̀ ìwádi tóòyẹ.

Ó wá rọ àwọn aráàlu Ìsẹ́yìn láti fowọ́ wọ́ọnú kíwọ́n sì fòpin sí àawọò tólè sokùnfà òfò ẹ̀mí àti dúkia nípinlẹ̀ ọ̀yọ́.

Gómìnà Makinde wá fọwọ ànfàní ìjọba àwarawa fáwọn èèyàn Ìsẹ́yìn sọ̀yà, tó sì sèlérí àtúnse komonkia ọ̀nà Ìsẹ́yìn soyo àti Ìsẹ́yìn Ogbomọsọ ki ètò ìsèjọba rẹ̀ tó paríì.

Elizabeth Idogbe

pub-5160901092443552

Related Posts

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *