Home Posts tagged Oba Abdulganiu Adekunle
Yoruba

Gómìnà ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́ sètò gbà mábinú fẹ́bí àwọn tópadùn ẹ̀mí wọn nílu Ìsẹ́yìn

Gómìnà ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́, onímọ̀ ẹ̀rọ Seyi Makinde ti sèlérí milliọnu kọ̀kan naira fẹ́bí àwọn tó sọ ẹ̀mí won nù nípase aawọọ ìbọn yínyìn lárin àwọn òsìsẹ́ ẹ̀sọ́ asọ́bọdè àtàwọn onífàyàwọ́ to waye nílu Ìsẹ́yìn. Ó sèlérí yíì lásìkò tó sàbẹ̀wò sáfin Asẹ́yìn ti Ìsẹ́yìn, ọba Abdulganiu Adekunle. Gómìnà Continue Reading