Yoruba

Ìgbìmọ̀ tẹkótó ilé asòfin kejì lórí ètò ìlera ti fọwọ́sí titọwọ àjọ elétò ìlera adójútofo, NHIS, bọmu àwọn isẹ́ àkànse tóníse pẹ̀lú ètò ìlera táwọn asòfin máà ń se lẹ́kùn ìdìbò kóòwá wọn.

Alága ìgbìmọ̀ tẹkoto le asòfin kejì náà, ọ̀mọ̀wé Tanko Sanunu ló kéde yíì nílu Abuja lákokò tákòwé àgbà àjọ NHIS, ọ̀jọ̀gbọ́n Muhammed Sambo farahan níwọnju ìgbìmọ̀ náà fọrọ àbá ètò ìsúná ọdún 2022.

Ọmọwe Sununu sàlàyé pé, bí isẹ́ àkànse tónsí pẹ̀lú ètò ìlera láwọn ẹkùn ìdìbò kóòkan bá ń gba abẹ kọjá, yóò fáwọn tón gbé láwọn agbègbè ìgbèríko atẹsẹ kuku lánfaní látara ètò ọ̀hún láifi teyikeyi ipose.

Nínú ọ̀rọ̀ tákọ̀wé àgbà àjọ, NHIS, ọ̀jọ̀gbọ́n Muhammad Sanubo, sọpé, àjọ náà ti sàgbékalẹ̀ ètò kan, tí yóò fẹnikookan àwọn ebi lanfani àti sanwó lórúkọ àwọn èèyàn agbègbè kóòwá wọn.

Folakemi Wojuade

News

Àjọ tó rísí ètò ìlera nípinll Èkó sọpé, ohun ti ńgbé ìgbésẹ̀ láti sàfikún àwọn olùgbé tóòtóò milliọnu mẹ́ta sínú ìlànà ètò ìlera adójútófo ti ìforúkọsílẹ̀ náà yóò sì wáyé lárin ọdún kan.

Alákoso àgbà fájọ ọ̀hún Dókítà Emmanuẹla Zamba, sọ èyí di mímọ̀ níbi ìpàdé ètò ìlanilọ́yẹ̀ àwọn èèyàn ẹsẹ kùkú àti ìgbésẹ̀ iforukọ sílẹ̀ tó wáyé nípinlẹ̀ náà.

Díkítà Zamba ẹnitó sàlàyé pé, ètò ìlanilọ́yẹ̀ àti iforukọ sílẹ̀ ọ̀hún sepàtàkì nítirípé ìlera lọrọ̀ àtọ́kasí.

Àwọn irinsẹ́ toye pe okolerugbaole méjì ló ti wan kanlẹ láti sètò iforukọ sílẹ̀ ná. Elizabeth Idogbe