Yoruba

Ìjọba  ìpínlẹ̀ Ògùn ti kéde pé, wọn yóò lé èyíkèyí àwọn akẹ́kọọ tó bá domi àláfìa ìkẹ́kọ́ọ̀ rú, láwọn ilé-ìwé gbogbo tó ń bẹ nípinlẹ̀ náà kúrò nílè wé.

Alákoso fétò ẹ̀kọ́ ìmọ̀ sáyẹ̀nsì àtìmọ̀ ẹ́rọ nípinlẹ̀ Ògùn, ọ̀jọ̀gbọ́n Abayọmi Arigbabu ló sísọ lójú ọ̀rs yíì nílu Abẹokuta lákokò tón báwọn oníròyìn sọ̀rọ̀ lórí báwọn akẹ́kọọ kan nílé-ìwé girama tójẹ́ tìjọba, se ;n diya jẹ, àwọn olùkọ́ wọn nítorípé wọ́n báwọn wí.

Ó fi kálèyé rẹ̀ pé, ìjọba kòní fàayè gba ìwà àilẹ́kọ àti àiníbawí èyí tíwọ́n loit gogo sára àwọn akẹ́kọ́ọ̀ kan, ó wá sèlérí pé, ilé isẹ́ rẹ̀ yóò wankan se si èyí tó wáyé náà, tí yóò sì sèwádi ohun tó sokùnfà irúfẹ́ ìwà tíkò tọ́ ọ̀hún.

Ọjọgbọn Arigbabu gba àwọn olùkọ́ tọ́rọ̀kàn níyànjú láti yan ìwà rere tí se ẹ̀sọ́ ènìyàn láàye, bẹ́ẹ̀ ló sì tún ké sáwọn òbí náà, láti lọ máà fi ohunkohun tó bá ń bíwọn nínú nípa olùkọ́ kan, tó ọ̀gá àgbà irúfẹ́ ilé-ìwé bẹ́ẹ̀ létí, fún ìgbésẹ̀ tó bá yẹ lórí rẹ̀, lái mu ìdájọ́ lọ́wọ́ ara wọn.

Folakemi Wojuade

News Yoruba

Gomina Ipinle Ekiti, Omowe Kayode Fayemi ti kede sisi ile iwe fun awon akeko ni ipele eko keji nile-eko-Girama-agba SS2 ipele eko keta nile eko Girama kekere JSS3 ati awon oniwe mefa alakobere bere lati ojo kokanlegun osu yi.

Bakanna awon akeke nipele eko-Girama kekere keji, JSS2 ati ikarun pry 4 ati 5 ni won yio wole ni ojo kejidinlogbon osu yi nigbati awon yoku yio wole ni ojo kokandinlogun osun to nbo.

Gomina Fayemi ninu oro to baa won eniyan ipinle naa so lori ibiti nkan de duro lori arun Covid 19 ni awon akeko kekeke ti a mo ni Sursery and Kindergarten ni won yio wole lojo keji osu kejila odun yi.

O ni awon iel eko giga nipinle naa le bere si ni silekun won bere lati ojo keji osu to n bo lo, leyi ti o ni yio da lori bi won ti se gbaradi, ti won si se tele awon liana ti won la kale to.

Gomina wa gba awon alase ile-eko giga lamonran lati jumo sise po pelu igbimo amuseya lori Covid 19 nipinle Ekiti lori itosona ati awon ohun ti oye ki won si ki won to silekun pada.

Ogunrinde/Dada