Ìjọba àpapọ̀ ńgbèrò láti kọ́ ọjà ìgbàlódé tíwọ́n yóò ti máà ta òkúta olówó iyebíye nílu ìbàdàn. Ìjọba ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́ ti fi ilẹ̀ saréè méjì kalẹ̀ fún isẹ́ àkànse náà. Alákoso fún ìdàgbàsókè ohun àlùmọ́nì, Ọ̀gbẹ́ni Ọlamilekan Adegbitẹ sọ èyí lágbègbè Ọjọọ, ní’jọba ìbílẹ̀ Akinyẹle níbi ayẹyẹ Continue Reading
Federal government is to commence the construction of an international gem stones market in Ibadan, Oyo State capital. To this end, the Oyo State government has allocated two hectares of land for the project. The Minister of Mines and Steel Development, Architect Olamilekan Adegbite stated this in Ojoo, Akinyele Local Government during an official handover […]Continue Reading