Yoruba

Ajo kan ti kii se tijoba tamosi Bode Akindele Yield Initiative, BAYI, so pe bi aadota awon eniyan ni yoo janfaani idanileko nipa eto ogbin lodun 2020 tawa yii lati madinku ba airise se to gbogo nile yii.

Oludari agba ajo BAYI, Ojise Olorun Adetunji Agbgoola lo soro yii di mimo lakoko abewo awon alabojuto ajo naa silese Radio Nigeria, Ekun Ibadan.

Ojise Olorun Agboola to so pe awon odo nlowo ninu awon iwa kan lawujo nitori aimo iwulo ebun tolorun fi jinkin won, wa so dimimo pe afojusun ajo BAYI ni lati lowo sawon ojokan ise aje teyi sile se se nipase ifowosowopo pelu ile ise Radio Nigeria.

Nigba ton naa nsoro, Oludari ile ise Radio Nigeria Ibadan, Alhaji Mohammed Bello sope ile ise Radio Nigeria ti setan lati gunle ajosepo pelu ajo BAYI fanfaani awon odo ile Nigeria.

Ajo BAYI loje ajo tafoju sun re je kiko awon odo lawon ona tiwon yoo file da duro fun ara won leka idokowo.

Ogunkola/Famakin

Lifestyle

A non-governmental organization also known as Bode Akindele Yield Initiative, BAYI, has solicited the support of the Federal Radio Corporation of Nigeria, FRCN, in its quest towards repositioning Nigerian youths for national development.

The Executive Director of Bode Akindele Yield Initiatve, Pastor Adetunji Agboola stated this during a courtesy visit of the organization to the management of FRCN, Ibadan Zonal Station.

Pastor Agboola said adolescents in Nigeria with development innovation were prone to social vices saying the vision of BAYI to catch them young to fulfill their life mandate would better be achieved through collaboration with Radio Nigeria.

Pastor Agboola said fifty thousand youths in the country be employed in the organization’s agricultural business to reduce poverty in the country.

In her remark, BAYI Programm Director, Mrs. Bukola Omosanya said Bode Akindele Yield Initiative organized community intervention as well as established BAYI clubs with fifty members in fifteen secondary schools and four tertiary institutions in the Southwest zone of Nigeria.

Mrs. Omosanya said the NGO would further broaden its interventions in 2020 to better reposition youths for development in the zone.

Reacting the Zonal Director, FRCN, Ibadan Zonal Station, Alhaji Muhammed Bello said FRCN is ready to partner Bode Akindele Yield Initiative to better the lots of Nigerian youths

Bode Akindele Yield Initiative is a non-governmental organization targeting youths for innovations, entrepreneurship, leadership, and development.

Rotimi Famakin