Yoruba

Igbimo to n mojuto yiye iwe owo wo ati eto atunto n’ileese ijoba nipinle oyo fun odun 2019/2020, ti da laba ki won yo awon osise ti won pe ni ayederu mokanlelogoji kuro lenu ‘se.

Igbimio naa tun fun awon osise miran ti won le ni aadorun niye, ti iwe akole ise won ko baramu, lanfani, lati momo kowe fi ise sile.

Iko alamojuto yi lo fie sun kana won osise to le ni egbeta niye, ti won si da laba lati yo won kuro, lori ate gbigba owo osu, a mo ti igbimo to n wa fun eto atunto, fese awon osise ayederu mokanlelogoji mule, awon mewa to ti papoda ati awon to fee woo igba ni won ni ko lo feyinti.

Ninu atejade eyi ti Oludamoran pataki si gomina lori oro iroyin, Ogbeni Taiwo Adisa, fi sita so pe abo iwadi ni won ti fi sowo ti won yo si je kawon osise to kan mo pato on ti ijoba fe, ki won se.

Iyabo Adebisi/Alolade Afonja

News Analysis

Ghost workers are individuals who receive salary from an organization without showing up for work or who may not exist but their salaries are appropriated by someone else. 

Federal, state and local governments in the country pay hundreds of millions of naira monthly to thousands of non-existent workers captured in their respective payrolls, thereby draining the governments of resources that could have been channeled into other productive ventures.

In 2011, for example, several state governments reported that they discovered six hundred to twenty thousand ghost workers on their payrolls.

The ghost worker phenomenon remains a menace troubling successive administrations at the federal and state levels.

For instance, former president, Goodluck Jonathan identified a solution to the scourge by setting up the Integrated Payroll and Personnel Information System, IPPIS, thus saving the federal government billions of naira paid annually to imaginary workers.

In February last year, President Muhammadu Buhari revealed that nearly five hundred and fifty million dollars has been saved from identifying ghost workers on the federal government’s payroll in the past four years.

Other states which recently uncovered the scourge include Kogi, Bauchi and Ekiti.

As a way of checking the recurring menace, some states have had to conduct biometric capturing of workers now and then to track the actual number of workers on their payroll.

No doubt, ghost workers increase the wage bill of government workforce above the wage budget which leads to budget overruns.

This phenomenon is worrisome as there would have been tremendous progress if the national wealth looted by those involved over the years had been channeled into education, health, power, agriculture, transportation and other sectors of the economy.

It is worth pointing out that, while the federal and state governments have always unraveled ghost workers, they have not recorded the same success in unmasking the architects of the economic crime, who must be people within the system, and apparently highly placed officials.

To nip the problem in the bud, government should not just engage in forensic auditing of the workforce but also go the long stretch of fishing out the culprits through thorough investigation by the police and other relevant agencies.

It is also imperative that periodic census of public service personnel and the maintenance of records of all official personnel including sacks, retirements and deaths, be strengthened. 

The achievement recorded through the use of the Integrated Payroll and Personnel Information System, IPPIS, initiated by the federal government in April 2007, which is saddled with the responsibility of payment of salaries and wages directly to government employee’s bank account with appropriate deductions and remittances has been notable.

States need to consider employing the milestone initiative for tracking financial flow to workers in agencies and departments in order to block leakages arising from phantom workers.

Above all, transparency and accountability remain essential to solving ghost workers challenges and nipping the menace in the bud.

Olusola Otunuga

Yoruba

Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkìtì ti sọ pé ìpínlẹ̀ náà ńpàdánù owó tó jẹ́ milliọnu lọ́nà ogún naira lórí àwọn ayédèrú òsìsẹ́ tó lé ọdurun níye láwọn ìjọba ìbílẹ̀ nípinlẹ̀ ọ̀hún.

Nínú àbọ̀ ìwádi èyí tígbìmọ̀ tón tọpinpin ìsẹ̀lẹ̀ náà tíjọba gbá kalẹ̀ fisíta.

Nígbà tón gbé àbọ̀ ọ̀hún fún Gómìnà Kayọde Fayẹmi nílu Adó-Èkìtì, alákoso fọ́rọ̀ tóníse pẹ̀lú ìjọba ìbílẹ̀ àti ìdàgbàsókè agbègbè, ọ̀jọ̀gbọ́n Adio Fọlayan, sọpé akápò àgbà ni wọ́n ti pa lásẹ fún láti dáwọ́ sísan owó osù dúró fún àwọn ayédèrú òsìsẹ́ wọ̀nyí.

Ọjọgbọn Fọlayan se lálàyé pé iye àwọn òsìsẹ́ yi ló jẹ́ ọ̀tàlélẹ́gbẹ́ta ólé méjì níye.

Ó sọ síwájú pé, ìgbìmọ̀ náà gba níyànjú pé kí wọ́n yọ owó tí wọ́n gbà lọ́nà àitọ́ yi kúrò nínú owó ìfẹ̀yìntì wọn, bákanà kí wọ́n mójú wọn balé ẹjọ́ lórí ẹ̀sùn líluni ní jìbìtì.

Nígbà tón gba àbọ̀ ọ̀hún, Gómìnà Kayọde Fayẹmi dúpẹ́ lọ́wọ́ ìgbìmọ̀ fún isẹ́ takuntakun tí wọ́n se tó sì sèlérí pé wọ́n yo gbé ìgbésẹ̀ kọ́mọ́nkìa lórí rẹ̀.

Tọpe Bamidele/Ọlọ́ládé Afọnja