Àjọ tó ń rísí ipeniye ohun tẹ́nu ń jẹ àti mimu pẹ̀lú egboogi lórílẹ̀èdè yí, NAFDAC, ti se ìfilọ́lẹ̀ tí kò pe níye, ǹkan ìpara tó léwu, omi inu ọrọ ti kò peye àti àwọn ǹkan ilo gbogbo tó kù diẹ káàto. Olùdarí àgbà àjọ NAFDAC, ọ̀jọ̀gbọ́n Mojisọla Adeyẹye ló se ìkìlọ̀ yí lásìkò tó […]Continue Reading
Iléèsẹ́ olóogun ofurufu ilẹ̀ yí ti sèkìlọ̀ fáwọn ọmọ orílẹ̀èdè yí tó n lépa àti wọlé sílé ẹ̀kọ́ gíga ìmọ̀ nọ́ọ̀si pé kí wọ́n sọ́ra kí wọn ma báà bọ́ sọ́wọ́ àwọn oníjìbìtì. Ìkìlọ̀ yí ló wáyé nípa ayédèrú ìwé ìgbaniwọlé sílé ẹ̀kọ́ náà tó ń lọ káàkiri orí ẹ̀rọ ayélujára. Olùdarí ètò ìròyìn ọ̀hún […]Continue Reading