Yoruba

Ajo eleto idibo nile yi inec, ti so pe gbogbo ipa to wa ni ikawo re ni yoo sa lati se to idibo ti koni eja nba kan nu ni ipinle ekiti .

Alakoso fun ajo inec lekun iwo orun gusu omowe adekunle ogunmola lo so oro yii ni ilu ado – ekiti nigbati ohun gba  awon eroja eto idibo na .

O si sope ajo na ti gbaradi fun eto idibo pelu oro idaniloju pee to idibo na yio yori sir ere .

Ninu oro alakoso fun ajo inec  ni ipile ekiti omowe adeniran tella sope awon on elo fun eto idibo niwon yoo gbe lo si awon ibudo ti won yoo tilo loju ojo

Akoroyin ile ise radio Nigeria jabo pee kun ila orun ekiti kinni loni wodu  marun pelu ibudo idibo metadilogoji  awon to si ti fi  oruko sile je egberun lona metalelogun ati otalelegbeta le mewa

Amos/Afonja

Yoruba

Gomina ipinle Ekiti, Omowe Kayode Fayemi ti pase ayewo arun COVID-19, awon oluko atawon akeko kokan lati mu adinku ba itankale aarun COVID-19 n’ipinle naa.

Gomina Fayemi ninu oro re lori afefe fawon eeyan, tokasi pe igbese ayewo arun, ti safihan opo arun COVID-19, to si sope igbese naa yoo tan de awon ile-eko.

O salaye pe ijoba ti safomo awon ile-iwe ijoba ti igbese is n je gbigbe lati san awon igboo, lati mu eto eko rorun pelu ayika too yee koroo.

Omowe Fayemi, fikun pe ijoba ti pese awon ohun tooye feeto abo lori arun COVID-19 laon ile-iwe ti igbimo kan siti je gbigbe kale lati maa sabewo sawon ile-eko.

Elizabeth Idogbe/Amos Ogunrinde

Yoruba

Gomina ipinle Ekiti, Omowe Kayode Fayemi ni ayewo ti fidi e mu’le pe oun ni arun Coronavirus.

Gomina Fayemi lo je koro yi di mimo lori opo ero ayelujara abeyefo re, pe ayewo eleeketa ti won se fun ni abajade re so pe oun ni arun naa lana.

Gomina loti lo y’ara re soto fun itoju pelu awon iko ilera t’oje t’ijoba.

Pelu isele yi, Gomina Fayemi ti ya awon ise to se koko, s’oto ki igbakeji Gomina, Otunba Bisi Egbeyemi l’ati tesiwaju ninu ise oba.

Babatunde Salaudeen/Oriola Afolabi