Yoruba

Bánki tón rísí àwọn ilésẹ́ olókowò, ọ̀hún ti satán láti pèsè owóya tí yo wọ billiọnu kan naira láti ró àwọn onísòwò lágbára nípinlẹ̀ Èkìtì.

Olùdarí àgbà fún ilé ìfowópamọ́ náà, nípinlẹ̀ Òndó àti Èkìtì, ọ̀gbẹ́ni Seyi Ashaolu ló jẹ́ kọ́rọ̀ yi di mímọ̀ nílu Adó-Èkìtì, tọ́kasi pé bánki náà setán láti yá àwọn olókowò àti ẹnìkọ̀kan tó fẹ́ dókowò papa lẹ́ka ìlera ìpèsè óujẹ ni wọn yo ni ànfàní láti yá owó.

Ó wá rọ àwọn alákoso, láti gbé ìlànà kalẹ̀, tí wọ́n yo fi gba àwọn owó tí wọ́n ti yá, lára àwọn onísòwò nípinlẹ̀ ọ̀hún padà.

Nínú ọ̀rọ̀ alákoso, ọ̀gbẹ́ni Muyiwa Olumilua gbóríyìn fún ilé ìfowópamọ́ tón rísí ìdókowò fún ìgbésẹ́ ìbásepọ̀ pẹ̀lú ìjọba ìpínlẹ̀ Èkìtì, tó sì sọ̀rọ̀ ìdánilójú pé gbogbo àtìlẹyìn tó yẹ nìjọba yo gbe nípasẹ̀, ilésẹ́ tón rísí okòwò àti àwọn ilésẹ́ ńláńlá.

Bákanà ni ó bu ẹnu àtẹ́lu, báwọn tó gba owó ọ̀hún tẹ́lẹ̀ se kùnà láti san padà, tó sì sọpé èyí tí wọn gbé kalẹ̀ báyi ni wọ́n yo pin nípasẹ̀ àwọn ẹgbẹ́ alájẹsékù, kó lè rọrùn fún ìjọba láti gbáà padà.

Ọlọlade Afọnja

Lifestyle

The Commissioner for Information in Ekiti state, Mr Muyiwa Olumilua has finally resolved the crisis rocking the state council of the Nigeria Union of Journalists, NUJ.

At a peace meeting held in his office in Ado Ekiti, Mr Olumilua pleaded with aggrieved members from the Broadcasting Service of Ekiti State, BSES and the state Ministry of Information to sheath their swords in the interest of peace and the union.

He told them to forget their grievances and join hands with the state officers so as to builds a virile union.

In his remark, the state chairman of NUJ, Mr Rotimi Ojomoyela thanked the commissioner for wading into the crisis and welcomed the aggrieved members back to the Union, with a pledge that all chapels would be carried along in the union’s activities.

Also speaking, NUJ chairman in BSES, Mr Bisi Oluwasona and his counterpart from the state ministry of Information, Mr Adeola Olofe promised to mobilise their members back to the union.

On his part, a former NUJ state chairman, who is now the special Adviser to the speaker of the Ekiti State House of Assembly on Media, Akogun Tai Oguntayo pleaded with aggrieved members to give peace a chance.

The NUJ members from BSES and the state ministry of Information had not been attending the union’s programmes since 2017 due to the outcome of the last election which produced Mr Rotimi Ojomoyela as chairman.

The peace meeting was attended by the Ekiti state chairperson of NAWOJ, Mrs Fatima Bello and NUJ members selected from other chapels. 

Amos Ogunrinde