Yoruba

Adari eto iroyin nileese Oloogun ile yi, Major General Benjamin Sawyer ti bere fun ajosepo pelu ileese Radio Nigeria nidi eto ironilagbara fawon osise re nipe iroyin gbigbe jade lori aseyori ileese ollogun lona ti aabo to peye yoo fi w anile yi.

O pe ipe yi nilu Abuja lasiko to saaju iko awon osise re lenu abewo solu ileese Radio Nigeria, lati se enle n beun si oludari agba ileese Radio Nigeria, Omowe Mansur Liman.

Ogagun Sawyer gbosuba fun leese Radio Nigeria nipa eto ironilagbara fun ileese Radio to je tileese ologun eyi to wa nilu Abuja, o wa pe fun itesiwaju ati ajosepo naa.

Nigba to n fesi, oludari agba ileese Radio Nigeria, Omowo Mansour Lima seleri igbaradi ileese, Radio Nigeria lati je ki ogagun naa se aseye talakan n sepo pelu pipolongo igbokegbodo ilees, oloogun fun isokan ile yi.

Babatunde Salaudeen

Yoruba

Ọgagun àgbà lórílẹ̀èdè yí, ọ̀gágun Faruk Yahaya ti rọ àwọn ológun ọ̀wọ́ kẹjọ iléèsẹ́ ológun ilẹ̀ yí pẹ̀lú àwọn ikọ̀ tí wọ́n pe ní Hadarin Daji pé kí wọ́n tẹpẹlẹ mọ́ igbokegbodo wọn nídi ogun gbigbe ti àwọn ukẹ agbesunmọmi.

Eyi ló jẹyọ nínú àtẹ̀jáde tí olùdarí ẹ̀ka ètò ìkede fún iléèsẹ́ ológun ọ̀gágun Onyeme Nwachukwu fi síta nílu Gusan ìpínlẹ̀ Zamfara.

Gẹ́gẹ́ bí àtẹ̀jáde náà se wí, ọ̀gágun Yahaya pàrọwà yí lásìkò tó ń bá àwọn ikọ̀ ológun náà sọ̀rọ̀.

Ó gbósùbà fún wọn lórí ìgbòkègbodo wọn nídi àti wagbo dẹ́kun fáwọn ọ̀daràn, kí ohun gbogbo ó léè tètè padà po sípò láwọn ìpínlẹ̀ tọ́rọ kan.

Babatunde Salaudeen