Yoruba

Igbìmọ̀ atọpinpin elétò ìdájọ́ se se aráàlu  nisekuse àtàwọn ìsẹ̀lẹ̀ miin tó fara pẹ́ tí dába owó tó tó billiọnu mọ́kànlélógún naira fún sisan owó gbà mábinú fáwọn tí ọlọ́pa bá gbẹ̀mí wọn lọ́nà àitọ́ pẹ̀lú àwọn ikọ̀ agbófinró mii.

Alága ìgbìmọ̀ náà, adájọ́ fẹ̀yìntì Young Ogola ló fojú ọ̀rọ̀ yí léde lásìkò tó ń jábọ̀ isẹ́ ìrújú ìgbìmọ̀ rẹ̀ fún Gómìnà Doye Diri nílu Yenogoa.

Adájọ́ fẹ̀yìntì Ogola sàlàyé wípé, ìwé ẹ̀sùn bíì àadọ́ta ni ìgbìmọ̀ náà rí gbà, tí wọ́n sì jábọ̀ níbamu pẹ̀lú ìwádi tí wọ́n se.

Nígbà tó ń gbé àbọ̀ ìgbìmọ̀ náà, Gómìnà Diri dúpẹ́ lọ́wọ́ ìgbìmọ̀ náà wípé bí wọ́n se se isẹ́ náà tọkàn tara, ó wá jẹ́jẹ àti gbé ìgbìmọ̀ tí yóò rí sí àmúsẹ àbá náà dìde láifi àkókò sòfò.

Babatunde Salaudeen

News Yoruba

Igbakeji oga olopa nile yi, ekun kokanla, Ogbeni Olasupo Ajani nfe kawon araalu dehin nidi iwa kikolu awon olopa tabi ilese olopa nigba yoowu ti awoo ba waye.

Ooga olopa ohun soro yi lasiko ipade re pelu awon torokan eyi towaye lolu ileese olopa, Ibadan.

 O salaye pe lati igba awoo ifehonnuhan ENDSARS, ibasepo laarin awon olopa ati awon araalu ti mehe, to si je okan latra ohun to n sokunfa bi aleekun se mba iwa odaran lorileede yi.

Saaju oga agba ileese olopa nipinle oyo, Arabinrin Ngozi Onadeko, sope pelu okan o jo kan ipenija tilese naa nkoju si; o n sa gbogbo ipa re lati ri daju pe Alafia joba nipinle Oyo.

Nigba toun n soro, alaga ajo to n risi ibasepo laarin ileese olopa ataraalu, PCRC, eka tipinle Oyo, Eniowo Peter Omofoye, seleri atileyin ati ibasepo to loorin ajo naa fun ilese olopa.

Makinde/Idogbe

News

Alakoso fun ileese olopa nipinle Oyo, Ngozi Onadeko, sope ilese naa yoo fawon olopa sowo lopo sawon enu iloro to wani Ago-Are, ati Tede nijoba ibile Atisbo nipinle Oyo.

Alakoso so eyi nibi ipade kan to se pelu awon osise eleto abo min ni agbegbe Ago-Are ati Tede nitori aawon to waye lenu loloyi to lowo awon odo agbegbe naa.

O tun salaye pe kose yii to pari, ipade min to tun waaye lati wojutu si gbomisi omi ooto ohun.

Okan lara awon oba-alaye lagbegbe toro naa ti se, Onitede tilu Tede, Oba Abdurauf Adebimpe enito soro loruko akowe re, Kola Ogunronbi benu ate lu iwa kooto awon odo ohun.

Nigba to un fesi, Gomina ipinle Oyo, onimoero Seyi Makinde, eniti Olubadamoran Pataki re foro abo.  Fatai Owoseni sojufun sope, ijoba koni kaare lati fi keele ofin gbe eni yoowu to be nda rugudu sile.

 Oluremi/Idogbe