Mr. Honour Sirawoo has been re-elected as President of Sports Writers Association of Nigeria, SWAN, for a second term of three years. Mr. Sirawoo was returned unopposed at the Triennial Delegates Conference of the Association held in Port Harcourt, Rivers state. Also elected were former Continue Reading
Ogunlọ́gọ̀ àwọn obìnrin ni wọ́n yan bí ológun lọ sílé ìjọba nílu Port-Harcourt láti lọ fi ẹ̀húnú hàn lórí ìsekupa àwọn ọ̀dọ́bìnrin ní àwọn ilé ìtura ọ̀tọ̀tọ̀ n’ípinlẹ̀ Rivers. Àwọn obìnrin shún ni wọ́n wọ asọ dúdú, tí wọ́n sìn késí ìjọba láti gbé ìgbésẹ̀ burúkú náà. Wọ́n tọ́kasi wípé gbogbo èyàn pátápátá lái yọ […]Continue Reading