Bí àwọn Mùsùlùmí lórílẹ̀èdè yíì, se darapọ̀ mọ́ àwọn akẹgbẹ́ wọn lágbayé láti sayẹyẹ ọjọ́ ìbí ànọ́ọ̀bì.

Àarẹ Muhammadu Buhari ti rọ àwọn èèyàn ilẹ̀ yíì láti sàmúlò àkókò yíì, fíì nawọ́ ìfẹ́ sáwọn èèyàn wọn gẹ́gẹ́ bí àwòkóse ànọ́bì.

 Nínú àtẹ̀gáde tí olùrànlọ́wọ́ pàtàkì fún àrẹ lórí ọ̀rọ̀ ìròyìn àti ìbáráalu sọ̀rọ̀, Garba Sheu Àerẹ rọ àwọn àráàlu paapaa àwọn ọ̀dọ́, láti dẹ̀hìn nídi ìwà yóòwu tóòlè dáà rúgúdù sílẹ̀, irúfẹ́ èyí tóò wáyé lákokò ìfẹ̀húnúhàn àipẹ́ yíì.

 Àarẹ Buhari sài tún fọwọ́ ìlérí rẹ̀, sọ̀yà, láti mú òsìsẹ́ ọlọ́pa yóòwù táje ìwà ìbájẹ́ bá símọ́ lórí, fún ìwà ìfipá múni yo kojú ìjìyà tóò yẹ tófimọ́ àwọn tó ńjí ohun ìní ìjọba gbé.

 Lórí ọ̀rọ̀ àrùn covid-19, Àarẹ Buhari tọ́kasi pé orílẹ̀èdè yíì ti se àseyọ́rí láti mójútó ìpèníjà náà pẹ̀lú bí àkọsílẹ̀ àarùn náà se ń fojojúmọ́ dínkù.

Afónja

pub-5160901092443552

Related Posts

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *