Gómìnà ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́, onímọ̀ ẹ̀rọ Seyi Makinde ti kí gbogbo àwọn mùsùlùmí nípinlẹ̀ ọ̀yọ́ kú oríre ọjọ́ ìbí òjísẹ́ ńlá Muhammad.

 Nínú àtẹ̀jáde èyí tí akọ̀wé àgbà lórí ọ̀rọ̀ ìròyìn sí Gómìnà, ọ̀gbẹ́ni Taiwo Adisa fisíta, Gómìnà rọ àwọn Mùsùlùmí láti gbé ẹ̀wù ìfẹ́, àláfìa, ìfiraẹnijì wọ̀.

Gómìnà Makinde tún fi àsìkò ọdún yi láti rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí gbogbo àwọn tọ́rọkàn láti dákun dábọ̀ gba àláfìa láye pẹ̀lú àtọ́kasí pé isẹ́ gbogbo èyà ní láti ridájú pé ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́ túnbọ̀ dárasi.

 Bákanà, ẹgbẹ́ àwọn Mùsùlùmí tó jẹ́ òsìsẹ́ agbóhùnsáfẹ́fẹ́ nílẹ̀ Nàijírìa, MMPN, ẹ̀ka ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́ rọ àwọn asíwájú nílẹ̀ yí láti wo àwòkọ́se ìhùwàsí òjísẹ́ ńlá Muhammad nínú èyí anu síse , níní ẹ̀rí ìfẹ́, wiwanisọkan jugbogboẹlọ ọ̀kan nínú ìdáwọ́lé wọn.

 Nínú àtẹ̀jáde èyí tí alága ẹgbẹ́ ohun Àlhájì Ridwan Fasasi fis;ita nílu’ bàdàn ni ọ̀rọ̀ yi ti jẹyọ, pẹ̀lú àtọ́kasí pé, híhùwà òdodo ni gbogbogbà, ló wà lára o n tólè gbé orílẹ̀èdè yí jòkè àgbà, dọ́gba pẹ̀lú àwọn ilẹ̀ tóti gòkè àgbà lágbayé.

Adebisi/Afọnja

pub-5160901092443552

Related Posts

  1. Quite insightful publish. Never thought that it was this simple after all. I had spent a excellent deal of my time looking for someone to explain this subject clearly and you’re the only 1 that ever did that. Kudos to you! Keep it up

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *