Àrẹ Muhammadu Buhari ti rọ àwọn asájú nílẹ̀ adúláwọ̀ láti mú àgbéga bá sísàmúlò, mímú òdinwọ̀n bá lílò ìjagun olóró, kí ìsọ̀kan àti àláfìa le débá ètò àbò láwùjọ lápapọ̀.

Àrẹ Buhari sọ̀rọ̀ yí lásìkò ìpàdé pàtàkì ẹlẹkẹrinla, ilẹ adúláwọ̀ ni mímú àgbéga bá àláfìa, ètò àbò, ìsọ̀kan, àti mímúkí rògbòdìyàn dópin nílẹ̀ adúlọ́wọ̀, pẹ̀lú bí wọ́n ti sen kojú ìdúkokò mọ́ni lórí ìgbésùmọ̀mí àtàwọn ìwà ọ̀daràn min.

Óní pẹ̀lú bí ìfẹnukò lórí àláfìa se tín pọsi, Àrẹ pè fún kóríyá lórí ìbásepọ̀ láàrin ọ̀kanòjọ̀kan ẹkun papa lórí ètò ọrọ̀ ajé.

Ajibikẹ/Afọnja

pub-5160901092443552

Related Posts

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *