Yoruba

Ilé isẹ́ ọlọ́pa nípinlẹ̀ Ọ̀yọ́ àti àjọ ọ̀tẹlẹ̀múyẹ́, DSS, ti tẹnumọ́ ìpinu wọn láti fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú àjọ áàbò araẹni láàbò ìlú, NSCDC, láti wá ojútu sí ìsoro ọ̀rọ̀ ààbò àti àwọn ìwà ọ̀daràn nípinlẹ̀ yí.

Ọga àgbà ilé isẹ́ ọlọ́pa nípinlẹ̀ Ọ̀yọ́ arábìnrin Ngozi Ọnadẹkọ àti akẹgbẹ́ rẹ̀ ọ̀gá àjọ DSS, arábìnrin Clara Onika ló sọ̀rọ̀ yí lásìkò tí wọ́n lọ sàbẹ̀wò sí ọ̀gá àgbà àjọ NSCDC, ọ̀gbẹ́ni Micheal Adaralẹwa.

Ọga àgbà àjọ DSS, gbóríyìn fún àjọ NSCDC fún bí wọn se máà ńtètè gbé ìgbésẹ̀ nídi gbígbógunti ìwà ọ́daràn nípinlẹ̀ yi nípaapajulọ nídi dídàabòbò ọ̀pá epo, fífi ọmọ sòwò ẹrú àti àbójútó àwọn ilé isẹ́ aláàbo aládani.

Níti ẹ̀, ọ̀gá ilé isẹ́ ọlọ́pa nípinlẹ̀ yi sọ wípé kò sí ìkùnsínú kankan láàrin ilé isẹ́ ọlọ́pa àti àjọ NSCDC, tó wà jẹ́jẹ́ ifọwọsowọpọwọn nídi dídàabòbò ẹ̀mí òn dúkia àwọn olùgbé ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́.

Nígbàtí ónfèsì, ọ̀gá àgbà àjọ NSCDC, nípinlẹ̀ ọ̀yọ́, ọ̀gbẹ́ni Adaralẹwa mọrírì àwọn adarí àjọ elétò áàbò méjèèjì tó wà sèlérí àti múkí ìbásepọ̀ wọn máà tlsíwájú.

Bákanáà ló rọ àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́ láti máà sátìlẹ́yìn fún àjọ NSCDC, lórí fifi ọrọ tó wọn láti léè gbogunti ìwà ọ̀daràn nípinlẹ̀ yi.

Rasheedah Makinde/Ọlọlade Afọnja

News Yoruba

.Àjọ àbò ara ẹni lábòú, ńfẹ́ kíì àjọsepọ̀ tó lóòrin kówà lárin gbogbo ilésẹ́ elétò àbò gbogbo, láti lè sisẹ́ papọ̀ wójùtú sí ètò àbò tó mẹ́hẹ nílẹ̀ yí.

Ọgagba àjọọ̀hún tuntun nípinlẹ̀ ọ̀yọ́, ọ̀gbẹ́ni Micheal Adaralẹwa ló sọ̀rọ̀ yí lásìkò àbẹ̀wò ẹnusẹ́ sí ọ̀gágba tó ń sànkóso ọgbà ẹ̀wọ̀n.

Ọgbẹni Adaralẹwa, tẹnumọ́ pé ìbásepọ̀ yi nìkan ló lè fòpin sí ìwà ọ́daràn láwùjọ tálafìa yo si jọ ba.

Ó sọ síwájú pé, àjọ àbò ara ẹni lábòlú ni kòní fàyègba, jiji dukia arálu, ìjínigbé àtàwọn ìwà ìbàjẹ́ miran láwùjọ lábẹ́ ìsàkóso rẹ̀.

Ọgagba ọgbà ẹ̀wọ̀n, ọ̀gbẹ́ni Ailewọn Noel sọ pé yàtọ̀ fún àjọsepọ̀ yio dara tawo òsìsẹ́ alábo bánlo irinsẹ́ ìjagun wọn láti dábòbò ẹ̀mí àti dúkia arálu dípò fún kíwọ́n ma lo fi dún kokò mọ́ ni láwùjọ.

Makinde/Afọnja

Yoruba

Àjọ ààbò ara ẹni láàbò ìlú, NSCDC, nípinlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti kó àwọn òsìsẹ́ rẹ̀ tó tó ẹgbẹ̀rún méjì àbọ̀ ló si tibu tóòro ìpínlẹ̀ yi láti ríì dájú pé kò sí àayè fún ìwà ọ̀daràn lásìkò pọ̀pọ̀sìnsìn ọdún ajinde.

Àtẹ̀jáde ti agbẹnusọ àjọ náà nípinlẹ̀ Ọ̀yọ́, Ọ̀gbẹ́ni Oluwọle Olusẹgun fi síta nílu Ìbàdàn sọ wípé kíkó àwọn òsìsẹ́ wọn lọ sí gbogbo ìjọba ìbílẹ̀ mktẹ̀ẹ̀tàlélọ́gbọ̀n àti ìjọba ìbílẹ̀ ondagbasoke márùndínlógójì tó wà nípinlẹ̀ ọ̀yọ́ se pàtàkì láti léè jẹ́kí àwọn ọmọlẹ́yìn Kristi se ayẹyẹ ọdún ajinde pẹ̀lú ìfọkànbàlẹ̀.

Rasheedah Makinde/Folakemi Wojuade

Crime

A military officer attached to Joint Task Force, Igbeti in Oyo State and identified as “Uthman Muhammed” has been crushed to death by a runaway trailer.

The accident occurred on the new Ibadan-Oyo expressway, Powerline, Moniya, Ibadan on Sunday afternoon.

A witness of the incident, Mr Ayotunde Ojo explained that the accident happened as a result of reckless driving by a Micra driver.

Mr Ayotunde said the Micra driver while trying to carry a passenger, did not park properly and this caused the soldier who was riding motorcycle behind the Micra to swerve suddenly in order to avoid ramming into taxi.

As a result of the sudden maneuver, the soldier was hit and crushed by an oncoming trailer and reportedly died on the spot.

An officer of Nigerian Security and Civil Defence Corps, NSCDC, who preferred anonymity, said they received a distress phone call before rushing down to the spot of the incident.

The corpse of the deceased officer has been evacuated by some officers of Nigeria Army from the Adekunle Fajuyi Cantonment while the runaway trailer had been tracked to Bodija area of Ibadan.

Olalekan Olayiwola

Security

Nigeria Security and Civil Defence Corps, NSCDC, Oyo state command has gotten a new Commandant.

He is Mr. Iskilu Akinsanya.

Before the new appointment, Mr. Akinsanya was the Commandant in charge of logistics at the headquarters, Abuja.

Mr. Akinsanya has taken over the mantle of leadership from the former Commandant, Dr John Adewoye who has been redeployed to Zone F in Abeokuta, Ogun state.

Addressing the management staff officers and men of the Command, the new Commandant enjoined them to put in more efforts towards the development of the corps.

He called on the officers and men to continue to protect lives and property as well as ensuring collaboration with other security agencies to make Oyo state safe.

Rasheedat Makinde  /Ridwan Fasasi