Obituary

The mother of Senator Ahmed Lawan, the President of the 9th Senate, Hajiya Halima Daja, has died.

She died in Gashua, Yobe State, Saturday night, October 14.

According to Lawan’s media adviser, Dr Ezrel Tabiowo, the mother of the former Senate President died at the age of 86.

The statement said Hajiya Halima Ibrahim will be buried on Sunday in Gashua according to Islamic rites.

“Funeral prayers will, thereafter, be said for the deceased at the Gashua Central Mosque, located in the Emir’s Palace.

“Senator Ahmad Lawan appreciates the outpouring of love and support already received from friends, relatives, and colleagues.

“The family would like to extend deepest gratitude to all those who have reached out and offered their condolences, thoughts, and prayers during this time of immense sadness. Your love and support have been a source of strength, and they are forever thankful”, the statement said.

Punch / Titilayo Kupoliyi

Yoruba

Adarí ilé ìgbìmọ̀ asòfin àgbà ilẹ̀ yíì, ọ̀mọ̀wé Ahmed Lawan sọpé ilé ti setán láti sàtúngbéyẹ̀wò òfin tó síse pẹ̀lú ilégbe ìjọba àpapọ̀ láti mú ìdúró réè bá ẹ̀ka náà kíì ìfẹsẹ̀múlẹ̀ tílẹ̀lé ìlànà yíì fáwọn ilésẹ́ aládani jẹ́ títẹ̀lé sansan.

Ọmọwe Lawan sọ èyí lásìkò tíì olùdarí ilésẹ́ tó ńrísí ilégbe ìjọba àpapọ̀, ọ̀gbẹ́ni Gbenga Ashafa, léwájú àwọn ikọ̀ kan réè sàbẹ̀wò sí adarí ilé asòfin àgbà lọ́fìsì rẹ̀.

Gẹ́bẹ́ bí adarí ilé sewípé, àtúnse ìlànà ilégbe ọhun jẹ́ ìgbésẹ̀ tó ti yẹ́ẹ̀ kówáyé lọ́jọ́ tótipẹ́,.

Ọmọwe Lawan wá rọ àwọn adarí lẹ́ka ohun lórí ìgbésẹ̀ tíwọ́n ńgùnlé láti jẹ́ mú isẹ́ méjì papọ̀.

Net/Elizabeth Idogbe

Yoruba

Olórí ilé ìgbìmò asofin nílè yíì Senato Almad Lawan ti késí àwọn olùdarí ilé ìwé lorileèdè yi láti sátúngbeyẹ̀wò àte ètò ẹ̀kọ́ ní gbogbo ẹ̀ka ètò ẹ̀kọ́ nílè yi.

Senato Lawan dába ọ̀rọ̀ yi nígbàtí ó nside ìjóko gbogbogbo lórí Ijíròrò lórí àbá òfin tí wọ́n fẹ́ fi ṣàgbékale àwọn ilé ẹ̀kọ́ gíga ìjọba àpapọ̀.

Ó ní àte ètò ẹ̀kọ́ ilẹ̀ yí tí nílò atungbeyewo tipetipe láti leè ta kangbọn ní ṣáá taa wà yi. 

Senato Lawan ni orílè èdè Nàìjíríà nílò àwọn olùkọ́ tí wọ́n bá òde òní mu ní pàájùlọ ní ìlànà ti ìgbàlódé.

Àwọn ilé ẹ̀kọ́ gíga mẹ́ta oun ni ilé ẹ̀kọ́ olukoni àpapò, Giwa ńipinle Kaduna, ilé ẹ̀kọ́ olukoni apapo Mutu Biyu ní ìpínlè Taraba àti ti Ibokun ńipinle Osun.

Yemisi Dada/Kemi Ogunkola

Yoruba

Adarí ilé ìgbìmọ̀ asòfin àgbà ilẹ̀ yíì Sẹ́nátọ̀ Ahmed Lawan, sopé orílẹ̀èdè Náijírìa nílò àdúrà kólè boorí àwọn ìpèníjà rẹ̀.

Sẹ́nátọ̀ Lawan sọ èyí nígbà tó ńgba àwọn asòfin tójẹ́ ọmọ lẹ́yìn Krístì lálejò.

Ẹgbẹ́ àwọn asòfin tó jẹ́ ọmọ lẹ́yìn Krítì ọ̀hún ní igbákejì adarí ilé Sẹ́nátọ̀ Ovie ọmọ-Agege àti akójanu ilé Sẹ́nátọ̀ Orji Uzor Kalu léwájú.

Adarí ilé wá rọ gbogbo ènìyàn láti kọ́kọ́ wá ojú Ọlọ́run kí ìdáhùn àdúrà lé wájú.

Ó fikun pé ojúse àwọn adarí ní láti máà fi ìgbàgbọ́gbo bèrè fún ìdásí Ọlọrun nínú ètò ìsèjọba àti fáwọn èèyèn àwùjọ.

Kẹmi Ogunkọla/Dada Oluwayẹmisi