Igbákejì àarẹ orílẹ̀dè yíì, ọ̀jọ̀gbọ́ Yẹmi Ọsinbajo sọpé, ìjọba àpapọ̀ ti nì óuń yóò sàtìlẹyìn fún ìlànà sìsanwó osù àwọn olùkọ́ ilé-ìwé aládaní àtàwọn onísẹ́ ọwọ́, láti pinwọ́ ipá tí ìtànkálẹ̀ àrùn covid-19 timì lórí ètò ọrọ̀ ajé wọn.

Níbi ètò àpérò ọlọ́dọọdún tẹ́gbẹ́ àwọn agbẹjọ́rò tónlọ lọ́wọ́ ọgọ́ta irú ẹ̀, lọ̀jọ̀gbọ́n Ọsinbajo ti sísọ lójú ọ̀rọ̀ ọ̀hún, pẹ̀lú àlàyé pé, ìjọba àpapọ̀ ti ní àwọn ilẹ lókanòjọ̀kan làwọn ìpínlẹ̀ mọ́kànlá tónbẹ nílẹ̀yíì láti fi kọ àwọn ilé gbe oníyàrá méjì-méjì fáwọn ọmọ orílẹ̀dè yíì tíwọ́n yóò sì máà ta ni milliọnu méjì-méjì naira fọ́kọ̀ọ̀kan .

Igbákejì ààrẹ kò sai tún se àlàyé pé, akitiyan ìjọba àpapọ̀ ni láti dábòbò isẹ́ fáwọn èèyàn tí ìtànkálẹ̀ àrùn covid-19 ti mú kétò ọrọ̀ ajé wọ̀n pakasọ.

Wojuade    

pub-5160901092443552

Related Posts

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *