Àarẹ orílẹ̀dè yíì, Muhammadu Buhari ti tẹnumọ́ ìpinnu ìjọba tó wà lóde báyíì láti fòpinsí báwọn ilé-isẹ́ apínná ká se máà ńbu owó láibítà fáwọn oníbarà wọn nílẹ̀ Nìajírìa.

Àarẹ Buhari tó sọ̀rọ̀ yíì di mímọ̀ nílu Abuja, tó sì sàlàyé pé, ìsèjọba òun yóò ridájú pé, iye iná ọba táwọn ọmọ orílẹ̀dè yíì bá ń lò nìkan ni wọ́n ń sanwó rẹ̀.

Àarẹ kò sài fi kálàyé rẹ̀ pe, ìjọba ti ń gbé ìgbésẹ̀ láti pín àwọn ẹ̀rọ tó ń ka iye iná ọba bi milliọnu kan lọ́fẹ gẹ́gẹ́ bí ìgbésẹ̀ àkọ́kọ́ nínú èyí tó lé ní milliọnu mẹ́fà ẹ̀rọ tó ńka iye iná ọba tóníbarà bá lò tíwọ́n fẹ́ pín yíká orílẹ̀dè yí.

Ololade Afonja

pub-5160901092443552

Related Posts

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *