Home Posts tagged Arábìnrin Evelyn Obidike
Yoruba

Àjọ NEPC Tẹnumọ́ Pàtàkì Síse Ìgbélárúgẹ Ọ̀rọ̀ Ajé Ilẹ̀yí

Àjọ tó mójútó fífi era sọwọ́ sókè òkun NEPC, ti tẹnumọ́ pàtàkì kí àwọn tón se okòòwò fífi ẹrù sọwọ́ sílẹ̀ òkèèrè se gbogbo ǹkan tó tọ́ fún fífi àwọn ọjà wọn sọwọ́ sí ọjà àgbáyé. Gẹ́gẹ́bí ọ̀gá àgbà àjọ ọ̀hún, Ọ̀gbẹ́ni Olusẹgun Awolọwọ sewí, àjọ NEPC, ló sàpèjúwe àwọn ìlànà fífi ǹkan sọwọ́ àti Continue Reading