Yoruba

Àjọ tó ńrísí ọ̀rọ̀ ilé ìwòsàn aláàbọ́dé nílẹ̀ yí ti sọ wípé orílẹ̀ èdè yi yio gba abẹ́rẹ́ àjẹsára COVID-19 Pfizer-Biontech, Modena àti oxford Astrazenica láàrin osù yí sí osù kẹsan ọdún yí.

Adarí àgbà fún àjọ náà, Dókítà Pheza Shuab ẹnití ó sọ̀rọ̀ yí di mímọ̀ nílu Abuja sọ wípé oníruru àwọn abẹ́rẹ́ àjẹsára yi ti ilẹ̀ America àti àjọ ìsọ̀kan ilẹ̀ adúláwọ̀ fi ta orílẹ̀ ede oyi lọ́rẹ ni yio de ni ìpele ìpele.

Nídi èyí, ìjọba àpapọ̀ ti ra irinsẹ́ U701 ultracode ibain tótó mokandín láàdọrin tí wọ́n fi ńse abẹ́rẹ́ àjẹsára lọ́jọ́ tí wọ́n si ti pín mktàdínlógójì sí gbogbo ìpínlẹ̀ mkrìndínlógójì àti olú ìlú yi ní ìgbáradì fún gbígba abẹ́rẹ́ àjẹsára covid-19 yi tó nílò láti tutu ni ìwọ̀n tí kò tó ogójì sí márùndínláàdọrun celcius.

Dókítà Shuab sọ wípé ilẹ̀ yí ti parí fífún àwọn ènìyàn ni abẹ́rẹ́ àjẹsára ìpele kini tó wà ní wọn tí bẹrẹ ìgbésẹ̀ lórí fífún àwọn ènìyàn lábẹ́rẹ́ ọ̀hún ní ìpele kejì.

Oluwayẹmisi Dada

Health

Dr. Cyprian Nyong, of the National Hospital, Abuja, has made history as the first front-line health worker to receive the COVID-19 vaccine today (Friday) in Nigeria, when he took the AstraZeneca/Oxford COVID-19 vaccine.

The vaccination was flagged off by the Chairman of the Presidential Task Force on COVID-19 and Secretary to the Government of the Federation, Mr Boss Mustapha, on behalf of President Muhammadu Buhari at the National Hospital Abuja.

In a speech shortly after the inoculation, Dr Nyong who has been at the Isolation Center since March last year expressed regrets the he lost his father to the Covid19 pandemic.

Minister of Health, Dr Osagie Ehanire

In an address, Minister of State for Health, Dr Olorunnimbe Mamora said Nigeria was on the verge at ensuring that all its citizens received the Covid19 Vaccination.

Dr Mamora noted that in a pandemic situation the ultimate was the use of Vaccine

Dr Mamora thanked all Covid19 partners, Frontline workers, arms of Government, and the media for their support in the fight against Covid19 pandemic.

Other personalities at the event included Speaker, House Reps, Femi Gbajabiamila, members of the Legislative chamber, international partners, religious leaders and traditional rulers

All protocols were put in place to ensure the safety needed in Administering the Covid19 Vaccine.

Okareh/Kutara/Maureen