News Yoruba

Gómìnà ìpínlè oyo, onímò èro Seyi Makinde tí ro àwọn ẹlẹ́sìn Islam láti máà tesiwaju lórí àjọṣepò tó dán mọran pẹ̀lú ìjọba kole sekunlowo fún ètò isejoba rere.
Ó soro náà nilu Ìbàdàn lásìkò ìpàdé àpapò ègbé akojopo àwọn ẹlẹ́sìn islam tekun Gúsù ìwọ orun, ìyẹn Muslim Human of South West Nigeria, MUSWEN, eleekefa irue nilu Ìbàdàn.
Gómìnà Makinde ti Olubadanmoran rẹ foro tó jẹ́ mo tesin islam, Alhaji Abdul Rasheed – Azeez soju fún ṣàlàyé pé, irúfé ajosepo bẹ yóò faaye gba igbora ẹni ye fún ìdàgbàsókè ìgbàgbépo àlàáfíà.
Èwe, nígbà tó n sọ̀rọ̀ lórí àkòrí tí wọ́n pè ní aiseto àbò nílè Nàìjíríà, ipa rẹ lórí ìhùwàsí ọmọniyan, olubanisoro níbi ètò náà túnṣe alamojuto ilé ìṣe olopa tẹ́lẹ̀rí omowe Yinka Balogun lodi ọrọ ṣíṣetó abo mọ aìdúró rẹ ìlànà isejoba ohun ailegbera tó ìjọba lórí àgbékalè àwùjọ tó dùnwọn ètò ẹ̀kọ́ tó mo yàn lórí ohun ìdàgbàsókè àwọn odo.
Omowe Balogun kò sai tún tọ́ka sí ìwà ajebanu tó ti di bárakú láwùjọ ileyi ohun àlàfo ńlá tówà laarin àwọn oloro àti àwọn tó kudie káto fún gẹ́gẹ́ bí nkan tó ń fa bile yí kòṣe n dele ìlérí.
Ṣáájú nínú ọrọ Ààrẹ ẹgbẹ́ MUSWEN, Alhaji Rasaki Oladejo loti tenumo pàtàkì ironi lágbára àwọn tí ò rowo orí fún wiwojutu soro àwọn tókù díè káto fún láwùjọ.

Adebisi /Olaopa

Yoruba

Gómìnà ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́, onímọ̀ẹ̀rọ Seyi Makinde ti sèkìlọ̀ fáwọn èèyàn láti yàgò kúrò nídi àwọn ìgbésẹ̀ kan, èyí tó lè yọrísí fífi tìpá tikuuku yo yan kan kúrò nípò tàbí léwọn kúrò nípinlẹ̀ ọ̀yọ́.

Ìkìlọ̀ yíì ló wáyé níbamu pẹ̀lú dàrúdápọ tó wáyé láàrin àwọn àgbẹ̀ àtàwọn darandaran kan lágbègbè òkè-ògùn nípinlẹ̀ ọ̀yọ́.

Gómìnà Makinde sàlàyé pé, ẹniyoowu tàbí ikọ̀ kankan tó ń bá gbèrò láti lọ kọlu àwọn èèyàn láti yàgò kúrò nídi isẹ́ bẹ́ẹ̀, torípé ìjọba òun kó tẹ́tí láti gbé ìgbésẹ̀ òfin tó bayẹ lórí ẹni tó bá ń gbìyànjú àti domi àlàfìa ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́ rú.

Ó tẹnumọ́ pé, ìsèjọba òun ti pinu, láti dábobo ètò gbogbo èèyàn tón gbé nípinlẹ̀ ọ̀yọ́, gẹ́gẹ́ bó se wá nínú àtúnse òfin ilẹ̀ yíì tọdún 1999.

wojuade

Yoruba

Gómìnà ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́, onímọ̀ ẹ̀rọ Seyi Makinde ti sèlérí láti sèpàdé pẹ̀lú alákoso fún ilésẹ́ ọlọ́pa nípinlẹ̀ ọ̀yọ́, ọ̀gbéni Joe Nwachukwu, láti ridájúpé ìgbésẹ̀ tóòyẹ jẹ́ gbígbé fún àbò gbogbo-gbò.

 Ó sọ̀rọ̀ yíì nílu ìbàdàn, lásìkò tó ńbá àwọn olùfẹ́húnúhàn tó ń gbèèrò láti dàànà sún ilésẹ́ ọlọ́pa Testing ground Idi-apẹ ìbàdàn.

 Lásìkò tó ńbá àwọn ọ̀dọ́ tí ńnú bíì ọ̀hún sọ̀rọ̀, Gómìnà Makinde pè fún àláfìa tó sì sèlérí láti bójútó ìréfun wọn.

  Gómìnà Makinde sàlàyé pé, ètò isẹbo tó ńléwájú tí sètò báwọn èèyàn tó ní àwọ̀ kan tàbí omin pẹ̀lú ìwà ipá ọlọ́pa yóò se máà fíì lsùn wọn hàn, pẹ̀lú àlàyé pé ojú-óòpó ayélujára kan tí jẹ́ sísí láti fẹ̀sùn wọn sọwọ́.

Adebisi/Idogbe

Yoruba

Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọyọ, onímọ̀ ẹ̀rọ Seyi Makinde ti ní ojú ò kán òun láti sílẹ̀ kùn àwọn ilé ìwé padà àyàfi tí òun bá gbọ́ ìmọ̀ràn láti ẹnu àwọn akọ́sẹmọ́sẹ́.

Ó sọ̀rọ̀ yi níbi àkànse ìjóko ilí ìgbìmọ̀ asòfin láti sàmì ayẹyẹ ọdún kan tí wọ́n fi ilé ìgbìmọ̀ asòfin ìpínlẹ̀ yi elẹ́kẹsan lọ́lẹ̀.

Ó rọ gbogbo àwọn tí wọ́n ńharagaga kí ìjọba sí àwọn ilé ìwé padà àti kíka òfin tó de ìpéjọpọ̀ ẹ̀sìn àti ayẹyẹ láti túbọ̀ se súùrù.

Gómìnà ní irú ìgbésẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni wọ́n yíò gbé lẹyin ti wọ́n báti sàgbéyẹ̀wò ìwádi tí àwọn akọ́sẹmọ́sẹ́ ńse lọ́wọ́.

Oluwayemisi Dada