By Oluwakayode Banjo The Oyo State Government has urged Education Secretaries to strive to impart discipline and sound morals within their Local Government Universal Basic Education Authorities for the overall good of the state. The government equally stressed the importance of the Continue Reading
Nidi ati wa ona abayo si isoro awon ewe to sa kuro nileewe lorileede yi, o se Pataki fawon toro eto eko gberu lati maa fowosowopo. Alaga ajo eleto eko kariaye nipinle Oyo, Omowe Nureni Adeniran lo pepe yi lasiko iforowero pelu akorinyin Radio Nigeria fun ti isami ayajo eto eko lagbaye. Omowe Adenitan kominu […]Continue Reading
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọyọ sọpé, òun kòní yíì ìpinu òhun padà láti gbé àwọn ilé ìwé alákọbẹ̀rẹ̀ aládani tí o kójú òsùwọ̀n tàbí àwọn tójẹ́ gbígbékalẹ̀ láibofinmu tìpa. Alága àjọ Subẹb nípinlẹ̀ Ọyọ, ọ̀mọ̀wé Nureni Adeniran sọ̀rọ̀ yíì di mímọ̀ nígbà tó ńbá àwọn oníròyìn sọ̀rọ̀ nílu Ìbàdàn. Ó sàlàyé pé ìgbésẹ̀ náà sepàtàkì nítorí báwọn […]Continue Reading