Home Posts tagged Nureni Adeniran
Yoruba

Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọyọ gbé ìgbésẹ̀ lórí àwọn ilé ìwé alákọbẹ̀rẹ̀

Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọyọ sọpé, òun kòní yíì ìpinu òhun padà láti gbé àwọn ilé ìwé alákọbẹ̀rẹ̀ aládani tí o kójú òsùwọ̀n tàbí àwọn tójẹ́ gbígbékalẹ̀ láibofinmu tìpa. Alága àjọ Subẹb nípinlẹ̀ Ọyọ, ọ̀mọ̀wé Nureni Adeniran sọ̀rọ̀ yíì di mímọ̀ nígbà tó ńbá àwọn oníròyìn sọ̀rọ̀ nílu Ìbàdàn. Ó sàlàyé pé ìgbésẹ̀ náà sepàtàkì nítorí báwọn […]Continue Reading