Home Posts tagged Premier FM Ibadan
Lifestyle

Heart 2 Heart: Love and Trust (Pt. 3)

Love and trust, trust and love. Can love exist, thrive and grow without trust? Can you really love without trusting? Join ‘Dayo Adenuga tonight, 15th March,by 9 30pm on Premier 93.5 FM for Season 3 of Love Vs Trust. You can also watch live via https://www.facebook.com/PremierFM935?mibextid=ZbWKwL Join and get to know the “Truths” you never […]Continue Reading
Yoruba

Olósèlú kan ńfẹ́ kí òfin wà lórí ipèsè isẹ́ fáwọn ọ̀dọ́

Ó yẹ kí ilé ìgbìmọ̀ asòfin gbé òfin ìjọba ìpínlẹ̀ láti pèsè isẹ́ fún ọ̀dọ́ tó bá ti pé ọdún mọ̀kànlélógún. Ọrọ yí ló tẹnu, olósèlú títún se olùdarí kan, ọ̀mọ̀wé Fọla Akinọsun jáde lásìkò tón kópa lórí ètò kan Premier F.M, tí wọ́n pè ní “The Stage”. Ọmọwe Akiọsun sọ pé ìjọba ní láti […]Continue Reading
Yoruba

Oga àgbà ilé-isé igbohunsafefe famonran síta lórí àwọn ètò tó ń jáde faraye gbó

Olùdarí àgbà ilé-isé Radio Nàìjíríà ẹkùn Ìbàdàn Alhaji Mohammed Bello, sọ pé àwọn tó ń ṣàgbékale ètò nilese náà gbodo lóye àwọn nkan tó ń ṣẹlẹ̀ láyìíká wọn, èyí tí yó jẹ́kí yàtò sáwọn toku, tíwọ́n yóò fi máa wà nípò iwájú. Lópin ìpàdé apero olọ́jọ́ méjì tó dá lórí àgbékalè àwọn ètò gbogbo, tó […]Continue Reading