Lola ode yi, ireti w ape ijoba apapo yo bere si ni ko awon eeyan ile Nigeria to wa ninu rogbodiyan laarin Ukraine ati Russia wale. Alakoso foro ile okere, Ogbeni Geaffrey Onyeama lo je koro yi di mimo lasiko ipade po pelu adari ile asofin agba, Ogbeni Femi Gbajabiamila. Ogbeni Onyeama so pe Continue Reading
Alaafin of Oyo, oba Lamidi Olayiwola Adeyemi has conferred chieftaincy title on member of the House of Representatives, Shina Abiola Peller Installing Shina Peller and his wife , Ayobola as the Ayedero and Yeye Ayedero of Yorubaland ,Alaafin charged him to assist in defending and uplifting the Yoruba race. According to Oba Adeyemi, the honour […]Continue Reading
Governor Seyi Makinde of Oyo State says his government will support any agenda geared towards promoting unity and regional integration among the Yorubas across the world to enrich culture and expand the economy. He gave the assurance when he received a delegation of Yoruba paramount ruler from Benin republic, and the Onimeko of Imekoland, led by […]Continue Reading
Àwọn tó fẹ́ gba ìtọ́jú kúrò lọ́wọ́ àrùn kókóró HIV nílèwòsàn ìjọba Heart to Heart nílu ọ̀yọ́ ńfẹ́ kí àmúbgòrò débá ètò ìgbáyégbádùn èyí tí ẹ̀ka tikise tìjọba gbé kalẹ̀, láti lèjẹ́ kí wọ́n lè borí ìpèníjà ètò ọrọ ajé tó ń bá ill yí fínra. Lára àwọn tó ní àrùn yí tó bá akọ̀ròyìn […]Continue Reading
Alákoso fọ́rọ̀ ìròyìn àti àsà, Àlhájì Lai Mohammed ti rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sáwọn ilẹ̀ tóti gòkè àgbà láti se àtìlẹ́yìn fún orílẹ̀èdè Nàijírìa pẹ̀lú àwọn irinsẹ́ tó yẹ láti lè wọ̀ yája pẹ̀lú ìgbésùnmọ̀mí. Ó rawọ́ ẹ̀bẹ̀ yí lásìkò tó se àbẹ̀wò ẹkúsẹ́ ńbẹun sí Gómìnà Samuel Ortom nílèjọba tó wà ní Markurdi. Àlhájì Muhammed sọ […]Continue Reading
Are egbe osise orile ede yii, Ogbeni Ayuba Wabba, ti sope oun yio ko awon osise Ipinle Ogun sodi lojo Jimoh lati fehonu han lori liana owo lile to Gomina Ibikunle Amosun na sawon osise ipinle naa. Ogbeni Wabba woye pe igbese naa yio waye lati jeki Gomina Amosun yanju gbogbo awon gbungbun oro to […]Continue Reading