Ìgbìmọ̀ amúsẹ́yá ìjọba àpapọ̀ fárùn covid-19 rọ àwọn èèyàn ilẹ̀ yíì láti sọdún kérésìmesì àti ìsinmi ọdún titun bótiyẹ.

Alága ìgbìmọ̀ náà títún se akọ̀wé ìjọba àpapọ̀ ọ̀gbẹ́ni Boss Mustapha ló sọ̀rọ̀ yíì nínú àtàjáde nílu Abuja.

Ọgbẹni Mustapha níì ó se pàtàkì, káwọn èèyàn mú ìgbésẹ̀ àbò wọn àti pípa àwọn ìlànà atẹle fárùn covid 19 mọ̀, láti fòpinsí ìtànkálẹ̀ àrùn covid 19, pẹ̀lú bí orílẹ̀dè yíì se ńkojú ìkẹ́rin àrùn náà.

Bakana lótún rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sáwọn èèyàn ilẹ̀ yíì, láti yàgò fún àpéjọpọ̀ ọ̀pọ̀ èrò.

Ọgbẹni Mustapha wá ni osese kí àjọ psc gbé ìgbásẹ̀ fífòpinsí àwọn àpéjọ kan, isede láwọn apá ipikan tí àkọsílẹ̀ àrùn náà bá tún búrẹ́kẹ́ síì.

Elizabeth Idogbe

pub-5160901092443552

Related Posts

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *