Ìgbìmọ̀ alásẹ ìjọba àpapọ̀ ti buwọlu isẹ́ àkànse mẹ́rìndílógún lójúnà àti mú àgbéga báà iná mọ̀nà-mọ́ná nílẹ̀ yíì.

Alákoso fóun àmúsagbára, Àlhájì Abubakar Aliyu sọ̀rọ̀ yíì fáwọn oníròyìn lẹ́yìn ìpàdé ìgbìmọ̀ alásẹ èyítí igbákejì ààrẹ ilẹ̀ yíì ọ̀jọ̀gbọ́n Yẹmi Osinbajo darí rẹ̀ nílu Abuja.

Ó níì ìpèníjà kan gbogi tó ńkojú ìdúró ree iná mọ̀nàmọ́ná nílẹ̀ yíì ní kíkùnà nídi pínpín iná mọ̀nàmọ́ná tówànílẹ̀ lọ́nà tóyẹ.

Alákoso ọ̀ún tọ́kasi pé, ibùdó apako pin soso lówà nílẹ̀ yíì níbití wọ́n ti kaseyọri le ba ẹ̀ka wọn.

Elizabeth Idogbe

pub-5160901092443552

Related Posts

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *