Yoruba

Ilésẹ́ tón rísí ìrìnà ojú irin ti fòfinde ìrìnà láti Abuja lọ sí Kaduna, tí kò sì ní gbèdéke.

Ilésẹ́ náà ló jẹ́ kọ́rọ̀ yí di mímọ̀ nínú ọ̀rọ̀ tó fi síta lójú òpó abẹ́yẹ fò twitter rẹ̀ lóòrọ yi.

Ó sọ pé ìfòfindè náà ló wáyé fún àwọn ìdí tí wọ́n kò lérò, tó sìní wọ́n yo sọ̀rọ̀ lórí rẹ̀ láipẹ.

Ilésẹ́ náà tún sọpé àwọn agbésùnmọ̀mí kan tún ju àdó olóró sí ojúrin Abuja lọ sí Kaduna, tí wọ̀n sì kojú ọkọ̀ ojúrin tó ní ọ̀pọ̀ èrò nínú lálẹ́ ọjọ́ ajé.

Bákanà ni wọ́n filéde pé àwọn ilésẹ́ alábo ti lọ sí ibi ìsẹ̀lẹ̀ náà.

Ikọ̀lú ọ̀hún ló wáyé, lẹ́yìn ọjọ́ diẹ, táwọn agbésùmọ̀mí kọlu pápákọ̀ òfurufú Kaduna, níbití wọ́n kò ti fàyè gba kí ọkọ̀ báàlù kó fóò.

Ololade Afọnja 

News Politics

Former Governor of Nasarawa State, Senator Abdullahi Adamu, has been declared National Chairman of the All Progressives Congress, APC.

Governor Abubakar Badaru of Jigawa State made this known at Eagles Square, Abuja, venue of the APC national convention, after an aye-and-nay vote, according to the Punch.

Earlier, the party had released its unity list which named the lawmaker as its National Chairman.

The the National Working Committee comprises;

1. Abdullahi Adamu – National Chairman

2. Abubakar Kyari – Deputy National Chairman (North)

3. Ema Enaukwu – Deputy National Chairman (South)

4. Otunba Iyiola Omisore – National Secretary

5. Festus Fuanter – Deputy National Secretary

6. Muhazu Bawa Rijau – National Vice Chairman (North Central)

7. Mustapha Salihu – National Vice Chairman (North East)

8. Salihu Lukman – National Vice Chairman (North West)

9. Ijeoma Arodiogwu – National Vice Chairman (South East)

10. Victor Giadom – National Vice Chairman (South South)

11. D.I Kekemeke – National Vice Chairman (South West)

12. Ahmed El-Marzuk – National Legal Adviser

13. Uguru Matthew Ofoke – National Treasurer

14. Bashir Usman Gumel – National Financial Secretary

15. Suleiman M Argungun – National Organising Secretary.

Culled/

News

The first batch of Ukraine based Nigerians stranded in the country following invasion by Russia have arrived in Abuja, Nigeria’s federal capital.

The report has it that, Ukraine based Nigerians arrived in the country on Friday morning from Romania.

Max Air flight VM602 from Bucharest landed in Abuja at about 7:10 AM with the next flight from Hungary currently being expected.

“To God be the glory, Max Air evacuation flight VM602 from Bucharest touched down in Abuja,” Abike Dabiri-Erewa, Chairman, Nigerians in Diaspora Commission, NiDCOM, confirmed.

According to a source, the federal government will give $100 each to the Ukraine returnees upon their arrival.

Samson Abiodun/TheNewsGuru.com

Politics

 President Muhammadu Buhari has finally signed into law, the Electoral Act Amendment Bill.

The President assented to the bill at past midday on Friday, at a brief ceremony held at the Council Chamber of the Aso Villa in Abuja.

The Vice President, Professor Yemi Osinbajo; President of the Senate, Ahmed Lawan, and Speaker of the House of Representatives, Femi Gbajabiamila, witnessed the signing of the bill.

The President received the bill from the National Assembly on the 31st of January for a second time after he returned the bill to the legislative arm.

President Buhari had told the National Assembly to remove the clause that had to do with direct primaries for political parties from the electoral act amendment bill.


Oluwakayode Banjo

Health

President Muhammadu Buhari has returned to Abuja after a successful engagement in the 6th European-African Unions summit in Brussels, Belgium.

While in Belgium, the President held bilateral meetings on the sidelines of the summit with other heads of government to boost the bond between their countries.

Under the auspices of the “G4”, the President and the Presidents of Algeria, South Africa, and Ethiopia, agreed to strengthen the platform for the resolution of the various issues confronting Africa.

At the summit, President Buhari drew attention to the imbalance in economic and trade co-operations between Europe and Africa, and called for a change in the trend.

The President sought the support of Europe to African Union’s efforts at stemming the new wave of manipulation of constitutions and the attendant coups in Africa.

He expressed delight about the inclusion of Nigeria among the 6 countries in Africa designated as manufacturing bases for Covid-19 vaccine.

Abdullah Bello

Politics

Ahead of February 19 Governorship Primary election of the All Progressive Congress in Osun state,Governor Adegboyega Oyetola has said he remained the aspirant to beat in the contest.

Governnor Oyetola stated this shortly after appearing before the Screening Committee of the APC at the party’s National Secretariat, Abuja.

The governor boasted that his achievements since he began steering the affairs of the state in the last three years , put him ahead of other aspirants.

“Recently, I began a strategic consultation with the party members to seek their support ahead of the primary election. And the reception has been very encouraging. So far, we have visited 18 councils.

“I don’t want to talk about individuals. But I believe that I remain the aspirant to beat,” Oyetola added.

He was accompanied to the party Secretariat by party leaders,friends, supporters and loyalists, including his cabinet members.

The former Osun Secretary to State Government, SSG, Alhaji Moshood Adeoti, was also at the party secretariat for screening.

Alhaji Adeoti hails from Iwo in Iwo Local Government Area of the State.

It would be recalled that the Oluwo of Iwo, Oba Abdulrosheed Akanbi, had charged his subjects to vote for the incumbent Governor.

Oluwo advised his subjects not to waste their resources and energy working against the second term agendum of the governor, saying only those that are not interested in the growth and development of the town in particular and Osun State in general would want to run against Governor Oyetola.

Abiodun Adeoye

Security

Sequel to the recent posting and appointment in the Nigerian Army, the newly appointed Commandant of the Army War College Nigeria, AWCN, Major General Bamidele Alabi has taken over command as the 5th Commandant in the annals of history of the premier Nigerian Army Institution from his predecessor, Major General Solomon Udounwa.

The colourful ceremony took place at the premises of AWCN, WU Bassey Barracks, Asokoro Abuja.

General Alabi is among the 5 pioneer Directing Staff of the College when it was established on 28 February 2017.

He is a member of 41 Regular Course of the Nigerian Defence Academy.

He is of the Nigerian Army Infantry Corps.

The new Commandant has held various appointments in command, staff and instructional capacity.

These  include, member of Directing Staff at the Armed Forces Command and Staff College, AFCSC, Jaji, Commanding Officer, Nigerian Battalion 29, NIBATT 29,  United Nations Mission in Liberia, UNMIL, and Commander 3 Brigade Kano, prior to  his appointment as Director of Studies and Coordination at AWCN.

He is also a Member of Nigerian Institute of Management, NIM, and a Senior Executive Fellow of the Harvard Kennedy School.

Some of the key Military Courses he attended include Senior Staff Course in AFCSC, Advanced Command and Staff Course in the United Kingdom and Higher Defence Strategic Studies Course at National Defence College Nigeria.

In his valedictory speech, the outgoing Commandant, Major General Solomon E Udounwa, who is now the Chief of Army Special Services and Programmes congratulated the new Commandant whom he described as integral part of the College having served as Directing Staff as well as Director of Studies prior to his recent appointment as Commandant.

He wished him a fruitful and successful tenure urging the entire College community to extend same cooperation and support rendered him to his successor so that the College will continue to succeed.

In his remarks, the new Commandant General Bamidele A. Alabi, promised to build on the legacy of the immediate past Commandant.

He also thanked him for his purposeful leadership and mentoring which he said spans for decades.

Highpoints of the event include signing of handing and taking over notes, presentation of College flag to the incoming Commandant, presentation of souvenirs, address to soldiers and Civilian Staff and Quarter Guards formalities.

Chukwuma Agbanusi

Economy

National Executive Council, NEC, will today consider the adoption of a report by its ad hoc committee on fuel subsidy removal and the increase of petrol price to N302 per litre.

Vice-President Yemi Osinbajo is expected to preside over the meeting, to be attended by all the governors and other federal officials.

The Trade Union Congress will on Thursday also take a position on the planned removal of the fuel subsidy by the Federal Government.

The TUC Deputy Secretary, Nuhu Toro, told newsmen in Abuja on Wednesday, that the congress would hold a meeting over the subsidy issue.

Also speaking, the Association of Senior Civil Servants of Nigeria opposed the plan by the Federal Government to remove the fuel subsidy and increase the pump price.

The ASCSN President, Tommy Okon, said his association and Nigerians would resist the move.

He said, “Of course, Nigerians are resting assured that they would be defended by our union; that’s why we are here and that’s why we are saying it is a wrong decision to take at this time when workers’ wages are still stagnant. No increase, they have not made any provision.

“The transport system has not been looked into. So, you just wake up and say you are removing fuel subsidies. Where in other climes has this been done? Even when you give the subsidy, is it not the wealthy few that still hijacked it? The fight is not about workers, it is what Nigerians must rise and resist.”

Okon stated that the union had already taken a position on the issue, insisting that “no sane government should at this point of economic harshness decide to impoverish the people.”

There have been fears of likely fuel price increase since the Minister of Finance and National Planning, Zainab Ahmed, announced the plan to remove petrol subsidy last June.

According to an online news medium, reported on Wednesday that a committee of the National Economic Council had recommended that petrol should be sold at N302 per litre from February when the government would cease to subsidize the petroleum products in the country.

The report explained that NEC made the recommendations last November. The recommendations were reportedly put forward by the NEC ad-hoc committee interfacing with the Nigerian National Petroleum Corporation on the appropriate pricing of PMS in Nigeria.

Punch/Taiwo Akinola

Lifestyle

Senator Kola Balogun has paid a courtesy visit to the Egyptian Ambassador in Abuja, as a follow up for a mutual relationship between him and Oyo South District, as well as Oyo State in general.

He said the meeting was aimed at discussing foreign direct investments into Oyo South ranging from large scale rice farming, power generation and foreign direct investments to Oyo State.

Senator Balogun hoped for positive impacts.

Adenrele Ajisefini/m.facebook.com

Yoruba

Apákan ilé alájàméjì tí wọ́n ńkọ́ lọ́wọ́ nílu Abuja ti dàwó pẹ̀lú olùgbé kan nínú ilé náà tó jọ́lọ́hun nípè.

Ilé ọ̀hún tó dàwó lówà lẹ́yìn Cites Estate lójú ọ̀nà pápákọ̀ òfurufú ní Jabi.

Ìsẹ̀lẹ̀ náà, gẹ́gẹ́bí ọ̀gá àgbà àjọ tó ń mójútó ìsẹ̀lẹ̀ pàjáwìrì ẹkùn Abuja, Àlhájì Abbas Idris sewi, ló sẹlẹ̀ lọ́wọ́ òru.

Òkú ẹni tó bá ìsẹ̀lẹ̀ ọ̀hún rìn ni wọ́n ni wọ́n ti gbé lọsí ilé ìwòsàn ìjọba àpapaọ̀ tówà lágbègbè Jabi nílu Abuja.

Gẹ́gẹ́bí Àlhájì Idris sewí, ó ní àwọn tón gbẹnu ilé àkọ́pa tì náà ni wọ́n ti dóòla lọ sí àyè mi kole dẹ́kun lílùgbàdì ikú òjijì mi pẹ̀lú bílé náà se n ya lulẹ̀ diẹ.

Ọmọlọla Alamu/Ayọdele Ọlaọpa

News

Obinna Echianu, an inmate of the Kuje Custodial Centre in Abuja who was also on death row has committed suicide.

The deceased was sentenced for murder of an Uber driver, Inalegwu Ali in Abuja, last year.

He hung himself with his clothes inside the prison’s toilet on Saturday. Obinna’s remains was discovered by other inmates, removed and deposited at the University of Abuja Teaching Hospital mortuary.

Although the deceased was sentenced to death, his lawyer had appealed his conviction. He was arraigned last year alongside one Everly Nnorom, by the police on five-count of armed robbery, unlawful possession of firearms, and culpable homicide.

The deceased was accused of dispossessing Ali of his Nissan Almera at Gosa pedestrian bridge, Airport Road, Abuja, and also killed him after the robbery.

His death was confirmed by Humphrey Chukwuedo, spokesman, Nigeria Correctional Service, Federal Capital Territory Command.

The spokesperson who confirmed the death on Monday said the body has been taken to the University of Abuja Teaching Hospital for an autopsy to determine the cause of death. Kogi Flames



Yoruba

Àjọ tó ń rísí ipeniye ohun tẹ́nu ń jẹ àti mimu pẹ̀lú egboogi lórílẹ̀èdè yí, NAFDAC, ti se ìfilọ́lẹ̀ tí kò pe níye, ǹkan ìpara tó léwu, omi inu ọrọ ti kò peye àti àwọn ǹkan ilo gbogbo tó kù diẹ káàto.

Olùdarí àgbà  àjọ NAFDAC, ọ̀jọ̀gbọ́n Mojisọla Adeyẹye ló se ìkìlọ̀ yí lásìkò tó ń síde ètò náà nílu Abuja.

Olùdarí àgbà náà sàlàyé wípé, èrèdí ètò ìpolongo náà ní láti se àtẹnumọ́ àti àmúgbòrò ojúse àjọ náà lọ́nà tí àwọn aráàlu kò fi ní bọ sínú ewu ayádèrú ńnkan tí wọ́n nílò.

Ọjọgbọn Adeyẹye sàlàyé wí pé àkọmọna ètò ipolongo náà ni ifẹsẹmulẹ ètò ìlera tó péye faraalu wípé yíyàgò fún àwọn tó ń ta egbogi alakapọ, àwọn tó léwu fún ago ara ẹ̀dá nínú ìpèsè oun tẹ́nu ńjẹ.

Babatunde Salaudeen.  

Yoruba

Ètò ìgbẹ́jọ asíwájú kan fún àwọn èyàn ilẹ̀ Biafra, IPOB, Nnamdi Kanu ẹni tọ́wọ́ àwọn agbófinro tún tẹ̀ lana, ni wọ́n yo tlsíwájú láti ma gbọ́ ìgbẹ́jọ́ rẹ̀ lọ́jọ́ kẹrindinlọgbọn osù tón bọ̀.

Nígbàtí ètò ìgbẹ́jọ́ bẹ̀rẹ̀, nílé ẹjọ́ gíga nílu Abuja, agbẹnusọ fún ìjọba Shuaibu Labaran bẹ̀bẹ̀ pé kí iléẹjọ́ tètè gbọ́ ẹjọ́ náà, láti lè mú kí ìgbépọ̀ ọ̀hún yá ní kánkán.

Ilé ẹjọ́ tún pa lásẹpé, kí wán tó fojú Kanu ba ilé ẹjọ́ ni kí wọn kan sí agbẹjọ́ró rẹ̀, pẹ̀lú bóse wà láhamọ́ ọ̀dọ̀ àwọn DSS.

Adájọ́ Binta Nyako wa sun àsìkò ìgbẹ́jọ́ kúrò ní ogúnjọ́ osù kẹwa sí ọjọ́ kẹrindinlọgbọn àti ìkẹtàdínlọ́gbọ̀n osù tónbọ̀.

Adájọ́ àgbà fún ilẹ yi tótúnse alákoso fétò ìdájọ́, ọ̀gbẹ́ni Abubakar Malami ẹni tóbá àwọn akọ̀ròyìn sọ̀rọ̀, nísejú ọ̀gágba ilésẹ́ ọlọ́pa Usman Baba àti agbẹnusọ fún ikọ̀ DSS, ọ̀mọ̀wé Peter Afunnaya sàlàyé pé bí ọwọ́ tun se tẹ Kanu lóníse pẹ̀lú àjọsepọ̀ pẹ̀lú àjọ ẹ̀sọ́ alábo nílẹ̀ Nàijírìa àti àwọn ilésẹ́ ọlọ́pa lágbayé Interpol.

Adájọ́ àgbà fikun pé, ẹ̀sùn tíwọ́n fi kan, Kanu lóníse pẹ̀lú ìgbésùnmọ̀mí ìgbìyànjú láti dójú ìjọba dé, kíkọ́ on ìjà olóró jọ lái gbàsẹ tófimọ́ kíkó ẹgbẹ́ tí kò bófimú jọ.

Seyifunmi Ọlarinde/Ọlọlade Afọnja

Yoruba

Ijoba apapo pelu ajosepo banky agbaye, yoo pin egberindinlaadota million dollar ni ipinle merindinlogoji to w anile yi, lati madinku ba ipa aarun covid-19.

Alakoso keji feto isunaa ati aato gbogbo, Ogbeni Clem Agba so eyi nilu Abuja.

O salaye pe, ipinle kokan yoo gba ogun million dollar, nigba tii million medoogun dollar yo je tolu-ilu yii FCT.

Alakoso Agba fikun pe, igbese naa waaye lati mu agbende ba eto oro-aje nibamu pelu mimu ileri Aare Buhari se nidi yiyo million mewa omo ile Nigeria kuro ninu ise ati osi.

Elizabeth Idogbe

Security

A new Commissioner of Police, Ngozi Onadeko, has been posted to the Oyo State Police Command.

The order was given by the Inspector General of Police, Mohammed Adamu on Monday, January 11, 2021.

The posting, with those of other Commissioners of Police to various other commands, is with immediate effect.

Posted to Ebonyi State Command as Commissioner of Police is Aliyu Garba, while Abubakar Umar Bature has been posted to Airport Command in Lagos State.

The newly-decorated Force Public Relations Officer, CP Frank Mba has also assumed the position of the Commissioner of Police in charge of Force Police Public Relations Office (FFPRO), Force Headquarters, Abuja.

Adeleke Adeyinka Bode has been made the Commissioner of Police in Kebbi State, while Philip Maku is thePolice Commissioner, Special Protection Unit (SPU), Force Headquarters, Abuja.

Others are CP, Sokoto State, Ali Janga Aji; CP, Armament, Force Headquarters, Abuja, Ohikere Idris; CP, Border Patrol, FHQ, Abuja, Haladu Musa Rosamson; CP, Cross River State, Sikiru Akande; CP, Enugu State, Mohammed Ndatsu Aliyu; CP Peacekeeping, Sadiq Idris Abubakar; CP, Delta State, Ari Mohammed Ali; CP, Counter Terrorism Unit, Olofu Tony Adejoh; CP, Imo State, Nasiru Mohammed; CP, OPS, DOPS, Yusuf Ahmed; CP, Adamawa, Aliyu Adamu Alhaji; CP, Training, DTD, Babaita Ishola; Commandant, PDCE, Alexander Nengi Wannang; CP, Ports Authority Police (PAP), Western Lagos, John Amadi and CP, Police College, Ikeja, Lagos, Daniel Sokari-Pedro.

Rasheedah Makinde

Yoruba

Alákoso tẹ́lẹ̀ fétò ìsúná, ọ̀mọ̀wé Ngozi Okonjo iweala ti fọwọ́ sọ̀yà fàwọn èèyàn ilẹ̀ yíì àtàwọn orílẹ̀èdè ilẹ̀ Africa tókù lóórí ìpèsè abẹ́rẹ́ àjẹsára fárùn covid-19, láti ìparí osù kini ọdún tónbọ̀.

Ó sọ̀rọ̀ yíì lẹ́yìn ìpàdé alátìlẹ̀kùmọ́rí se pẹ̀lú alákoso fọ́rọ̀ ilẹ̀ òkòrè, ọ̀gbẹ́ni Geoffrey Onyeama nílu Abuja.

Ọmọwe Okonjọ Iweala, tise asojú àjọ ìsọ̀kan ilẹ̀ adúláwọ̀ lórí wíwá àtìlẹ́yìn àwọn ilẹ̀ òkèrè nídi ìgbésẹ̀ gbígbógunti àrùn covid-19 kéde pé ìlànà ilẹ̀ òkèrè yíì ní iléwòsàn àjọ elétò ìlera lágbayé W.H.O àti àgbàríjọ àwọn orílẹ̀dè àgbáyé, nídi gbíbgáradì fún àjàkálẹ̀ àrùn niwọ́n ti fẹnukò láti kó àwọn abẹ́rẹ́ àjẹsára lọ sáwọn orílẹ̀dè tó se nse ńdìde lẹ àtàwọn tóò kúrẹtẹ̀ lọ́nà tí ó gáà jara lọ.

Ó fikun pé, lọ́wọ́-lọ́wọ́ báyíì wọ́n ti ń dúna-dúrà lórí báwọn orílẹ̀dè tó kù diẹ káto fún yóò sẹ̀sẹ̀ tètè rí abẹ́rẹ́ náà gbà lái ni tóò lẹ́yìn àwọn orílẹ̀dè tó ti làmì laka.

Net/Elizabeth Idogbe

Yoruba

Ajo elepo robi ile yi, NNPC ti kilo fun awon eniyan alti mase foya lori rira awon eroja epo robi.

Ikilo yi lo waye latari iberu to be sile nilu Abuja ati agbegbe re bi awon eniyan ti se nto ra epo.

Agbenuso ajo NNPC, Ogbeni Kehinde Obateru ni ko si idi kankan lati ko okan soke nitori won ni eroja to too lo nile.

 Ogbeni Obateru salaye wipe bi awon gomina ti se nde ofin isede bayi gbogbo nkan to nip e pada bo sipo laipe.

O wa tenumo wipe ajo NNPC ni eroja to too o lo, to wa ro awon oni ile epo lati mase gba epo pamo.

Oluwayemisi Dada

Security

President Muhammadu Buhari is presently presiding over the National Security Council meeting at the Presidential Villa, Abuja

Vice president Yemi Osinbanjo Secretary to the Government of the Federation Boss Mustapha and Chief of Staff to the President, Ibrahim Gambari are present at the meeting

Also in attendance are the Minister of Defence Bashir Salihi Magashi, the Minister of Interior Rauf Aregbesola and that of Police Affairs, Muhammad Maigari Dingyadi

All the service chiefs and the Inspector General of Police are present at the meeting

The Director General of the National intelligence Agency, Ahmed Rufai, the Director General of the Department of State Security Service, Yusuf Bichi are present at the National Security meeting.

FRCN Abuja

Yoruba

Ile-ise Radio Apapo ile wa, FRCN, ti beere fun titunbo nawo to joni sile se ohun, ko le ba maa sise re gege bi ise, nibamu pelu ife Araalu.

Oludari Agba patapata funleese Radio Nigieria, Omowe Mansur Liman lo parowa yi nibi ipade ita gbangba kan to waye nilu Abuja, lakoko to n dahun awon ibere lolokan o jokan latodo agbarijopo igbimo tekoto ile Asofin Agba lori owo isuna ataabo gbogbo, tofimo tigbaradi fagbekale liana, owona f’odun 2021 s’odun 2023.

Omowe Liman so fun igbimo tekoto ile Asofin Agba ohun pe ile-ise naa nilo owo goboi lati paaro awon irinse tojo tilo lori won nilese ohun, pelu alaye igbese bawon ajo ijoba kan-kan se sanwo ise tiwon se, lori afefe, ko sanfani Kankan fun ile-ise ohun.

Alaga Igbimo tekoto ile Asofin Agba feto isuna, Senator Solomon Olamilekan wa gba ile ise FRCN niyanju lati gunle awon liana eyi tiwon file tunbo maa rowo pawole labele.

Eto ipade itagbangba naa lo wayelati fi wojutu si aba eto isuna ile yee lai fise ipalara fenikankan.

Folakemi Wojuade

Transportation

Passengers returning to their destinations after the Eidel kabir celebration in Ibadan may likely experience slight increase in the transport fare.

The development followed the limited numbers of passengers expected to be carried by transporters as well as possible increase in the volumes of passengers later in the week.

During a visit by our correspondent to Ojoo, Iwo Road and Challenge Motor Parks, it was observed that few passengers were still noticed while little hike was observed compared to what obtained before.

At Ojoo, Radio Nigeria observed that Ibadan to other states in the northern region cost between 7, 500 and 9, 050 naira while other states in the South-South from the ancient city cost between 5, 500 and 10, 000 naira, Ibadan to Abuja on the other hand cost 8, 000 naira.

Confirming the fare, at Iwo road, two park managers, Mr Daniel Odiniya and Felix Bayode said Ibadan five passengers were the numbers specified for each car to allow for physical distancing.

A transporter at Ojoo, Mr Motuf Olatunbosun said Ibadan to Sango Ota and other axis in Lagos costs between 1,500 and 2,500 naira.

Radio Nigeria also observed that Ibadan to Akure and Ado Ekiti ranged between 2,000 and 2,500 naira.

A passenger, Mr Adegoroye Oluwole said government should cushion the effects of the coronavirus pandemic through financial assistance for the transporters.

It was however observed that few passengers complied with the safety protocols of wearing the masks while other passengers in the buses do not observe physical distancing.

Rotimi Famakin

Transportation

Ahead of the reopening of flight Operations in Nigeria, the Federal Airports Authority of Nigeria FAAN has commenced the fumigation of the Lagos, Abuja and Port-harcourt International airports.

The fumigation exercise is against the Coronavirus pandemic ravaging the world.

It is not clear yet when the ban on Flights will be lifted but the agency is taking this proactive steps to ensure the safety of passengers and other Airport users when the gateways are reopened.

In March this year, the Agency embarked on a similar exercise of disinfection and fumigation of all the international airports.

With the extension on the ban on flight Operations by 4 weeks last month by the Chairman, Presidential Task Force, PTF on Covid19, and Secretary to the Government of the Federation, Mr. Boss Mustapha, it is hoped that by June, flight Operations may resume, however, the ban is still subject to review.

Nosa Aituamen

Politics

The Independent National Electoral Commission, INEC says the fire that occurred at the commission’s headquarters in Abuja would not affect its operations in any way as nothing significant was destroyed.

INEC’s National Commissioner and Chairman, Information and Voter Education Committee, Mr. Festus Okoye made this known in statement issued in Abuja.

Mr. Okoye explained that the fire broke out around 11:30am at a section of the building housing the Election and Party Monitoring Department and the Media Centre.

He said the fire was quickly contained by the firefighters attached to the commission with the assistance of their colleagues from the Federal Fire Service Headquarters, in the Federal Capital Territory, FCT.

The INEC Official noted that as a result of the quick action of the firefighters, apart from some office equipment and furniture, nothing sensitive was lost to the fire.

He said the reports of party primaries and conventions contained in the annex affected by the fire were intact as well as records of campaign finances.

Mr. Okoye added that investigation into the cause of the fire has commenced with the assurance that the administrative and technical operations of INEC would not be affected in any way by the fire.

Maxwell Oyekunle

Crime

The Media Centre of the Independent National Electoral Commission in Abuja has been engulfed by fire.

Details of the incident are sketchy as of the time of filing this report.

INEC National Commissioner and Chairman of its Information and Voter Education Committee, Festus Okoye, confirmed the incident to newsmen.

More details later…

Health

The Minister of Health, Dr Osagie Ehanire says International travel into Nigeria has been limited to two airports, to enable proper screening of arriving travellers into the country.

The minister stated this while giving updates on the Coronavirus pandemic in Abuja. 

Dr Ehanire said the two airports are Muritala Muhammed International Airport, Lagos and Nnamdi Azikiwe International Airport, Abuja while domestic flights are not included.

He also stated that Nigeria has identified Austria and Sweden as two more high-risk countries within the past 24 hours.

The minister stressed that people who just returned from infected countries in the last 3 weeks and people who have had close contact with someone who has either tested positive or who just returned from a foreign trip are eligible for testing as the test kits and reagents are becoming too scarce for random testing.

He urged people who just got back from foreign trips to self-isolate for a minimum of 14 days to protect others and reduce chances of infecting others noting that self-Isolation is a social responsibility, in order to protect members of their family, community and society.

Dr Ehanire said the federal government is aggressively involved in contact tracing of people who have contact with anyone who has tested positive to the virus.

Bunmi Agboola/Maxwell Oyekunle