Lóòrọ̀ òní, àwọn òsìsẹ́ ọba ni kò rọrùn fún láti wọ ilésẹ́ ìjọba ní Secretariat, Agodi ìbàdàn, lẹ́yìn tí àwọn tó ní ìpèníjà ara ńfẹ̀húnúhàn lórí ẹ̀sùn pé ìjọba dẹ́yẹ sí wọn. Akọ̀ròyìn ilésẹ́ Radio Nigeria jábọ̀ pé àwọn àkàndá ẹ̀dá yi ni wọ́n ńgbé oníruru àkọlé lọ́wọ́ láti fi ẹ̀húnúhàn wọn hàn. Continue Reading
Yoruba News
Weekend Treat
Trending Now
Recent Posts
Categories
Archives
iframe: google.com, pub-5160901092443552, DIRECT, f08c47fec0942fa0
This is the head of your page
This is the body of your page.