Ègbé olùkọ́ láwọn ilé ẹ̀kọ́ Fáṣítì nileyi, ASUU tí sewele iyanselòdi olosu mejo rẹ pẹ̀lú àwọn afẹnukò ìlànà kan.

Alága ẹgbẹ́ náà fún olú ìlú wa Abuja, Ojogbon Kasimio Umar ló fìdí ọ̀rọ̀ náà múlè fáwọn akoroyin nilu Abuja. 

Ègbé náà pinnu láti fòpin sí iyanselòdi ohun lásìkò ìpàdé àwọn adarí tó bẹ̀rẹ̀ lalẹ àná eleyi tó parí laaro yi.

Ìpàdé ohun lẹgbẹ ASUU pé láti forí okoo sọọdúnrun lórí ìlànà tókàn lẹ́yìn tí igun ẹgbẹ́ ohun sepade lórí ìdájọ́ ilé ejo kotemilorun tó wáyé lose tó kọjá.

Taába gbàgbé pé ilé ẹjọ́ kotemilorun ló pàṣẹ fẹ́gbé ASUU láti sewele iyanselòdi tó gunle.

Ní báyì náà, àwọn ọmọ ìgbìmò ẹgbẹ́ náà leyi tari àwọn alaga ńipinle àtàwọn tokun ni wọ́n pèjù síbi ìpàdé náà tó wáyé lolu ilé isẹ ẹgbẹ́ ASUU nilu Abuja.

Alamu/olaopa

Subscribe to our Telegram Channel and join our Whatsapp Update Group

pub-5160901092443552

Related Posts

Leave a Reply

Your email address will not be published. Required fields are marked *