Ìjọba àpapọ̀ tin kọminú bí iye àwọn tóní àisàn iba ọ̀rẹ̀rẹ̀ seń pọ̀si láwọn ìpínlẹ̀ kọ̀kan. Alákoso fétò ìlera, Dókítà Ọlọrunnibẹ Mamora ló fìdí ọ̀rọ̀ yí múlẹ̀ nílu Abuja pẹ̀lú àtọ́katí pé pẹ̀lú bí àsìkò ẹ̀rùn se ń wọlé dé, wọ́n ti ń fi ìdí ìsẹ̀lẹ̀ àisàn náà múlẹ̀ láwọn ìpínlẹ̀ kọ̀kan nílẹ̀ yí. Continue Reading
Yoruba News
Weekend Treat
Trending Now
Recent Posts
Categories
Archives
iframe: google.com, pub-5160901092443552, DIRECT, f08c47fec0942fa0
This is the head of your page
This is the body of your page.