Home Posts tagged Gomina Fayẹmi
Yoruba

Ìgbọ́kànlé nínú àwọn ọlọ́pa ló léè fẹsẹ̀ ètò àbò múlẹ̀ – Gomina Fayẹmi

Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkìtì ọ̀mọ̀wé Kayọde Fayẹmi ti tẹnumọ́ ìdí tó fi yẹ kí àtúntò ó wáyé lórí ọ̀nà fáwọn ọmọ ilẹ̀ yí yóò fi ní ìgbọkànlé nínú ilésẹ́ ọlọ́pa wípé àti se àseyọrí nínú ìpèsè ètò ààbò àwùjọ gbérù, léyi tó níì se pẹ̀lú àwọn àjọ elétò àabò àwọn òsìsẹ́ ìjọba, àwọn olósèlú àtàwọn Continue Reading