Àarẹ orílẹ̀dè yíì, Muhammadu Buhari ti sọ́ọ̀di mímọ̀ pé, ìsèjọba òun ti n wójùtú sọ́rọ̀ ilégbe fáwọn ọmọ orílẹ̀dè yíì, papajùlọ àwọn tó ń gbé láwọn ìlú ńlánlá. Lákokò tó ń sèfilọ́lẹ̀ àwọn isẹ́ àkànse ilégbe, abala àkọ́kọ́ nílu Òsogbo, tí sólùlú ìpínlẹ̀ Ọsun, áàrẹ sísọ lójú ọ̀rọ̀ náà. Áàrẹ Continue Reading
Aákoso fọ́rọ̀ abẹ́lé nílẹ̀ yí, ọ̀gbẹ́ni Rauf Arẹgbẹsọla ti sọ̀rọ̀ di mímọ̀ pé, káàdi ìdánimọ̀ ill yí tuntun fáwọn ọmọ ilẹ̀ yí yóò na ìjọba ní òbítíbitì owó. Ọgbẹni Arẹgbẹsọla sípaya ọ̀rọ̀ yí fáwọn oníròyìn nílu ilésà pẹ̀lú wí pé number fún káàdi ìdánimọ̀ ilẹ̀yí tó se pàtàkì lákokò yí fún gbogbo ọmọ ilẹ̀ yí […]Continue Reading